Publicidade

Neemias 4

Àtakò àtúnkọ́ odi Jerusalẹmu

1 Nígbà Sanballati gbọ́ àwa ń tún odi náà mọ, ó bínú, ó bínú púpọ̀. Ó fi àwọn ará Júù ṣe ẹlẹ́, 2 ó sọ níwájú àwọn ẹlẹgbẹ́ rẹ̀ àti níwájú àwọn ọmọ-ogun Samaria , "ni àwọn aláìlera Júù wọ̀nyí ń ṣe yìí? Ṣé wọn yóò odi wọn padà ni? Ṣé wọn yóò ẹbọ ni? Ṣé wọn yóò parí i rẹ̀ lóòjọ́ ni ? Ṣé wọ́n òkúta a ti sun láti inú òkìtì padà bọ̀ sípò ó jóná wọ́n ṣe ?"

3 Tobiah ará Ammoni, ẹni ó lẹ́gbẹ̀́ rẹ̀, , "Ohun wọ́n ń mọkọ̀lọ̀kọ̀lọ̀ lásán gùn ún sókè, yóò fọ́ odi òkúta wọn lulẹ̀!"

4 Gbọ́ ti wa, Ọlọ́run wa, nítorí àwa di ẹni ̀gàn. ̀gàn wọn padà sórí ara wọn. o fi wọ́n fún ìkógun ilẹ̀ ìgbèkùn. 5 ṣe bo ̀bi wọn tàbí wẹ àwọn ̀ṣẹ̀ wọn kúrò níwájú rẹ, nítorí wọ́n bínú níwájú àwọn ̀mọ̀.

6 Bẹ́̀ ni àwa mọ odi náà títí gbogbo rẹ̀ fi ìdajì gíga rẹ̀, nítorí àwọn ènìyàn ṣiṣẹ́ pẹ̀gbogbo ọkàn an wọn.

7 Ṣùgbọ́n nígbà Sanballati, Tobiah, àwọn ará Arabia, ará Ammoni, àti àwọn ènìyàn Aṣdodu gbọ́ àtúnṣe odi Jerusalẹmu ti ga òkè àti a ti mọ àwọn ibi ó , inú wọn gidigidi. 8 Gbogbo wọn jọ gbìmọ̀ pọ̀ láti Jerusalẹmu àti láti dìde wàhálà í. 9 Ṣùgbọ́n àwa gbàdúrà Ọlọ́run wa, a yan olùṣọ́ ̀sán àti ti òru láti kojú ìhàlẹ̀ yìí.

10 Lákòókò yìí, àwọn ènìyàn Juda , "Agbára àwọn òṣìṣẹ́ ti dínkù, àlàpà púpọ̀ ni ó bẹ́̀ àwa fi le è mọ odi náà."

11 Bẹ́̀ ni àwọn ̀wa , "wọn mọ̀ tàbí wọn wa, àwa yóò ti àárín wọn, a ó pa wọ́n, a ó iṣẹ́ náà dúró."

12 Nígbà náà ni àwọn Júù ó ń gbé ̀gbẹ́ wọn sọ fún wa ìgbà mẹ́wàá , "Ibikíbi ̀yin padà , wọn yóò kọlù ."

13 Nítorí náà mo ènìyàn díẹ̀ dúró níbi ó rẹlẹ̀ lẹ́yìn odi ibi gbangba, mo fi wọ́n síbẹ̀ nípa àwọn ìdílé wọn, pẹ̀àwọn idà wọn, àwọn ̀kọ̀ wọn àti àwọn ọrun wọn. 14 Lẹ́yìn ìgbà mo wo àwọn nǹkan yíká, mo dìde mo fún àwọn ọlọ́àwọn ìjòyè àti àwọn ènìyàn tókù , "ṣe bẹ̀u wọn. rántí Olúwa, ẹni ó tóbi, ó ̀, fún àwọn arákùnrin yín, àwọn ọmọkùnrin yín, àwọn ọmọbìnrin yín, àwọn ìyàwó yín àti àwọn ilé yín."

15 Nígbà àwọn ̀wa gbọ́ àwa ti mọ èrò wọn àti Ọlọ́run ti á jẹ́, gbogbo wa padà ibi odi, ẹnìkọ̀̀kan ibi iṣẹ́ tirẹ̀.

16 Láti ọjọ́ náà lọ, ìdajì àwọn ènìyàn ń ṣe iṣẹ́ náà, nígbà àwọn ìdajì tókù múra pẹ̀̀kọ̀, asà, ọrun àti ìhámọ́ra. Àwọn ìjòyè pín ara wọn sẹ́yìn gbogbo ènìyàn Juda. 17 Àwọn ẹni ó ń mọ odi. Àwọn ń ru àwọn ohun èlò ṣe iṣẹ́ náà pẹ̀ọwọ́ kan, wọ́n fi ọwọ́ kejì di ohun ìjà , 18 olúkúlùkù àwọn ̀mọ̀fi idà wọn ̀gbẹ́ wọn wọ́n ṣe ń ṣiṣẹ́. Ṣùgbọ́n ọkùnrin ń fọn ìpè dúró pẹ̀mi.

19 Nígbà náà ni mo sọ fún àwọn ọlọ́, àwọn ìjòyè àti àwọn ènìyàn tókù , "Iṣẹ́ náà fẹ̀ ó pọ̀, a ti jìnnà ara wa púpọ̀ lórí odi. 20 Níbikíbi ti gbọ́ ohùn ìpè, da ara pọ̀ mọ́ wa níbẹ̀. Ọlọ́run wa yóò fún wa!"

21 Bẹ́̀ ni àwa ṣe iṣẹ́ náà pẹ̀àwọn ìdajì ènìyàn ó di ̀kọ̀ , láti òwúrọ̀ kùtùkùtù títí di ìgbà ìràwọ̀ yóò fi yọ. 22 ìgbà náà mo tún sọ fún àwọn ènìyàn , "Jẹ́ olúkúlùkù ènìyàn àti olùrànlọ́wọ́ rẹ̀ dúró Jerusalẹmu òru, nítorí wọn le jẹ́ ̀ṣọ́ fún wa òru, wọn le ṣe iṣẹ́ ̀sán." 23 Bẹ́̀ ni èmi àti àwọn arákùnrin mi àti àwọn ènìyàn mi àti àwọn ̀ṣọ́ ó pẹ̀mi bọ́ aṣọ wa, olúkúlùkù wa ohun ìjà tirẹ̀, kódà nígbà wọ́n ń lọ pọn omi.

Veja também

Bíblia Online Bíblia Online

Bíblia Online • Versão: 2026-07-04_21-26-40-