Pular para o conteúdo
Publicidade

Neemias 8

1 gbogbo àwọn ènìyàn ara wọn jọ ẹnìkan gbangba ìta níwájú ibodè omi. Wọ́n sọ fún Esra akọ̀ó gbé ìwé òfin Mose jáde, èyí Olúwa ti pàṣẹ fún Israẹli.

2 ọjọ́ kìn-ín-ní oṣù keje ni àlùfáà Esra gbé ìwé òfin jáde iwájú ìjọ ènìyàn, èyí ó jẹ́ àpapọ̀ ọkùnrin àti obìnrin àti gbogbo àwọn ènìyàn wọ́n le è gbọ́ àgbọ́. 3 Ó á sókè láti òwúrọ̀ títí di ̀sán ó ti kọjú ìta iwájú ibodè omi ojú u gbogbo ọkùnrin, obìnrin àti àwọn ènìyàn tókù òye le è wọ́n níbẹ̀. Gbogbo ènìyàn fetísílẹ̀ ìwé òfin náà pẹ̀ìfarabalẹ̀.

4 Akọ̀Esra dìde dúró lórí i pẹpẹ ìdúrólé a fi igi kàn fún ètò yìí. ̀gbẹ́ rẹ̀ ̀tún ni Mattitiah, Ṣema, Anaiah, Uriah, Hilkiah àti Maaseiah gbé dúró , ̀gbẹ́ òsì rẹ̀ Pedaiah, Misaeli, Malkiah, Haṣumu, Haṣabadana, Sekariah àti Meṣullamu dúró .

5 Esra ṣí ìwé náà, gbogbo ènìyàn le í nítorí ó dúró níbi ó ga ju gbogbo ènìyàn lọ; ó ti ṣí ìwé náà, gbogbo ènìyàn dìde dúró. 6 Esra yin Olúwa, Ọlọ́run alágbára; gbogbo ènìyàn gbé ọwọ́ wọn sókè, wọ́n , "Àmín! Àmín!" Nígbà náà ni wọ́n wólẹ̀ wọ́n sin Olúwa ìdojúbolẹ̀.

7 Àwọn LefiJeṣua, Bani, Ṣerebiah, Jamini, Akkubu, Ṣabbetai, Hodiah, Maaseiah, Kelita, Asariah, Josabadi, Hanani àti Pelaiahkọ́ wọn ni òfin náà àwọn ènìyàn ṣe ìdúró síbẹ̀. 8 Wọ́n láti inú ìwé òfin Ọlọ́run, wọ́n túmọ̀ rẹ̀, wọ́n ṣe àlàyé ohun wọ́n à le àwọn ènìyàn yékéyéké.

9 Nígbà náà ni Nehemiah ó jẹ́ baálẹ̀, Esra àlùfáà àti akọ̀, àti àwọn Lefi wọ́n ń kọ́ àwọn ènìyàn fún gbogbo wọn , "Ọjọ́ yìí jẹ́ ọjọ́ mímọ́ fún Olúwa Ọlọ́run yín. ṣe ṣọ̀fọ̀ tàbí sọkún," nítorí gbogbo àwọn ènìyàn ti ń sọkún wọ́n ti ń tẹ́̀rọ̀ inú òfin náà.

10 Nehemiah , "lọ gbádùn oúnjẹ yàn láàyò ohun dídùn, díẹ̀ ránṣẹ́ àwọn . Ọjọ́ yìí, mímọ́ ni fún Olúwa wa. ṣe banújẹ́, nítorí ayọ̀ Olúwa ni agbára yín."

11 Àwọn ọmọ Lefi gbogbo ènìyàn dákẹ́ jẹ́, wọ́n , "dákẹ́, nítorí mímọ́ ni ọjọ́ yìí. ṣe banújẹ́."

12 Nígbà náà ni gbogbo ènìyàn lọ láti jẹ àti láti mu, wọ́n fi ìpín oúnjẹ ránṣẹ́, wọ́n ṣe àjọyọ̀ pẹ̀ayọ̀ ńlá, nítorí báyìí àwọn òfin a sọ di mímọ́ fun wọn ti wọn.

13 ọjọ́ kejì oṣù náà, àwọn olórí, gbogbo ìdílé, àti àwọn àlùfáà àti àwọn ọmọ Lefi, péjọ sọ́dọ̀ Esra akọ̀, wọ́n fi ara balẹ̀ láti fetí àwọn ̀rọ̀ òfin. 14 Wọ́n ri àkọsílẹ̀ nínú ìwé òfin, èyí Olúwa ti pa àṣẹ nípasẹ̀ Mose, àwọn ọmọ Israẹli gbé inú àgọ́ àkókò àjọ àgọ́ oṣù keje 15 àti wọn kéde ̀rọ̀ yìí, wọn tàn án kálẹ̀ gbogbo ìlú wọn àti Jerusalẹmu: "jáde lọ ìlú olókè, àwọn ̀ka inú olifi àti ̀ka igi olifi igbó, àti láti inú maritili, àwọn imọ̀ ̀pẹ àti àwọn igi ó léwé dáradára , láti ṣe àgọ́"—gẹ́gẹ́ a ti kọ ́.

16 Bẹ́̀ ni àwọn ènìyàn jáde lọ, wọ́n àwọn ̀ka , wọ́n kọ́ àgọ́ fún ara wọn orí òrùlé ara wọn, àgbàlá wọn àti àgbàlá ilé Ọlọ́run àti ìta gbangba lẹ́gbẹ̀́ ẹnu ibodè omi àti èyí ó lẹ́gbẹ̀́ ẹnu ibodè Efraimu. 17 Gbogbo ìjọ ènìyàn wọ́n padà láti ìgbèkùn kọ́ àgọ́, wọ́n ń gbé inú wọn. Láti ọjọ́ Jeṣua ọmọ Nuni títí di ọjọ́ náà, àwọn ọmọ Israẹli ì ṣe àjọyọ̀ rẹ̀ irú èyí. Ayọ̀ wọn pọ̀.

18 Esra nínú ìwé òfin Ọlọ́run, ọjọ́ ṣe ń gorí ọjọ́, láti ọjọ́ kìn-ín-ní ọjọ́ ìkẹyìn. Wọ́n ṣe àjọyọ̀ àjọ náà fún ọjọ́ méje, ọjọ́ kẹjọ wọ́n àpéjọ, ìbámu pẹ̀òfin.

Veja também