Publicidade

Provérbios 15

1 Ìdáhùn pẹ̀lẹ́ ìbínú padà

ṣùgbọ́n ̀rọ̀ líle máa ń ru ìbínú sókè.

2 Ahọ́n ọlọ́gbọ́n a máa gbé ìmọ̀ jáde

ṣùgbọ́n ẹnu aláìgbọ́n ń ̀rọ̀ òmùgọ̀ jáde.

3 Ojú Olúwa níbi gbogbo,

Ó ń wo àwọn ẹni búburú àti àwọn ẹni rere.

4 Ahọ́n ń ìtura jẹ́ igi ìyè

ṣùgbọ́n ahọ́n ̀tàn ń pa ̀run.

5 Aláìgbọ́n ọmọ kọ ìbáwí baba rẹ̀

ṣùgbọ́n ẹni ó gbọ́ ìbáwí jẹ́ ọlọ́gbọ́n.

6 Ilé olódodo kún fún ̀pọ̀lọpọ̀ ohun ìṣúra,

ṣùgbọ́n èrè àwọn ènìyàn búburú ń ìyọnu fún wọn.

7 Ètè olódodo ń tan ìmọ̀ kalẹ̀;

ṣùgbọ́n bẹ́̀ fún ọkàn aláìgbọ́n.

8 Olúwa kórìíra ìrúbọ àwọn ènìyàn búburú

ṣùgbọ́n àdúrà olódodo tẹ́ lọ́rùn.

9 Olúwa kórìíra ̀àwọn ènìyàn búburú,

ṣùgbọ́n ó fẹ́ràn àwọn ń lépa òdodo.

10 Ẹni ó kúrò lójú ̀yóò ìbáwí gan an,

ẹni ó kórìíra ìbáwí yóò .

11 Ikú àti ìparun ṣí sílẹ̀ níwájú Olúwa,

mélòó mélòó nínú ọkàn àwọn ènìyàn.

12 Ẹlẹ́gàn fẹ́ ẹni ń ba :

gbàmọ̀ràn lọ́dọ̀ ọlọ́gbọ́n.

13 Inú dídùn máa ń ojú túká

ṣùgbọ́n ìbànújẹ́ ọkàn máa ń pa ̀run.

14 Ọkàn olóye ń ìmọ̀

ṣùgbọ́n ẹnu aláìgbọ́n ń fẹ́ ìwà òmùgọ̀ ẹní jẹun.

15 Gbogbo ọjọ́ àwọn olùpọ́njú jẹ́ ibi,

ṣùgbọ́n onínúdídùn ń jẹ àlàáfíà ìgbà gbogbo.

16 Ó sàn ó pọ̀, ìbẹ̀Olúwa

ju ọrọ̀ púpọ̀ pẹ̀ìyọnu.

17 Oúnjẹ ewébẹ̀ níbi ìfẹ́

sàn ju àbọ́pa màlúù tòun ti ìríra.

18 Ènìyàn onínú ríru ìjà sílẹ̀

ṣùgbọ́n onísùúrù paná ìjà.

19 ̀̀lẹ ni ̀gún ,

ṣùgbọ́n ̀olódodo geerege ni.

20 Ọlọ́gbọ́n ọmọ inú baba rẹ̀ dùn,

ṣùgbọ́n aṣiwèrè ènìyàn kẹ́gàn ìyá rẹ̀.

21 Inú ènìyàn aláìlóye a máa dùn ìwà òmùgọ̀;

ṣùgbọ́n olóye ènìyàn a máa rin ̀tààrà.

22 Ìgbèrò a máa dasán níbi ìmọ̀ràn;

ṣùgbọ́n a máa yege níbi ̀pọ̀lọpọ̀ olùbádámọ̀ràn .

23 Inú ènìyàn a máa dùn nígbà ó fèsì yẹ

̀rọ̀ ó lásìkò yẹ dára púpọ̀!

24 ̀ìyè ń lọ sókè fún ọlọ́gbọ́n

láti sọ ó à sọ̀kalẹ̀ lọ ipò òkú.

25 Olúwa fa ilé onígbèéraga ya lulẹ̀,

ṣùgbọ́n ó pa ààlà opó onírẹ̀lẹ̀ mọ́ láìyẹ̀.

26 Olúwa kórìíra èrò ènìyàn búburú, ṣùgbọ́n mímọ́ ni ̀rọ̀ ẹni pípé.

27 ̀kánjúwà ènìyàn ìyọnu ilé rẹ̀

ṣùgbọ́n ẹni ó kórìíra àbẹ̀tẹ́lẹ̀ yóò .

28 Ọkàn olódodo ń wọn ìdáhùn

ṣùgbọ́n ẹnu ènìyàn búburú ń ibi jáde.

29 Olúwa jìnnà ènìyàn búburú

ṣùgbọ́n ó ń gbọ́ àdúrà olódodo.

30 Ojú túká máa ń ayọ̀ fún ọkàn,

ìròyìn ayọ̀ ń ìlera sínú egungun.

31 Ẹni ó fetí ìbáwí ń fún ni ìyè,

yóò àpéjọpọ̀ àwọn ọlọ́gbọ́n.

32 Ẹni ó kọ̀ ìbáwí kẹ́gàn ara rẹ̀,

ṣùgbọ́n ẹni ó gbọ́ ìbáwí yóò ìmọ̀ i.

33 Ìbẹ̀Olúwa kọ́ ènìyàn ọgbọ́n,

ìrẹ̀lẹ̀ ni ó máa ń ṣáájú ọlá.

Veja também

Bíblia Online Bíblia Online

Bíblia Online • Versão: 2026-07-05_12-11-46-