Publicidade

Provérbios 2

6 Nítorí Olúwa ni ó ń fún ni ọgbọ́n,

láti ẹnu rẹ̀ ni ìmọ̀ àti òye ti ń .

7 Ó to ìgbàlà fún àwọn olódodo,

Òun ni asà fún àwọn ń rìn déédé,

8 Ó pa ipa ̀ìdájọ́ mọ́

Ó ń pa ̀àwọn àyànfẹ́ rẹ̀ mọ́.

Veja também

Publicidade
Bíblia Online Bíblia Online

Bíblia Online • Versão: 2026-06-28_14-13-17-