Publicidade

Provérbios 28

1 Ènìyàn búburú ń ó tilẹ̀ jẹ́ ẹnìkan e

ṣùgbọ́n olódodo láyà i kìnnìún.

2 Nígbà orílẹ̀-èdè orí kunkun, àwọn ọba rẹ̀ a máa pọ̀,

ṣùgbọ́n olóye àti onímọ̀ a máa pa òfin mọ́.

3 Ọba ó ni àwọn tálákà lára

dàbí àgbàrá òjò ó ń gbá gbogbo ̀gbìn lọ.

4 Àwọn ó kọ òfin sílẹ̀ a máa gbóríyìn fún ènìyàn búburú

ṣùgbọ́n àwọn ó pa òfin mọ́ kọjú ìjà ènìyàn búburú.

5 Òye ìdájọ́ òdodo àwọn ẹni ibi

ṣùgbọ́n ó àwọn ń Olúwa dáradára.

6 Ó sàn láti jẹ́ tálákà ìrìn rẹ̀ jẹ́ aláìlábùkù

ju ọlọ́rọ̀ ̀rẹ̀ pálapàla.

7 Ẹni ó pa òfin mọ́ jẹ́ olóye ọmọ

ṣùgbọ́n ẹni ó ́ jẹgúdújẹrá kẹ́gbẹ́ dójútì baba rẹ̀.

8 Ẹni ó ọrọ̀ rẹ̀ di púpọ̀ nípa èrè àjẹjù

ń jọ fún ẹlòmíràn, yóò àánú àwọn tálákà.

9 ẹnikẹ́ni kọ etí ikún òfin,

kódà àdúrà rẹ̀ jẹ́ ìríra.

10 Ẹni ó olódodo rìn ̀búburú

yóò bọ́ sínú pàkúté ara rẹ̀

ṣùgbọ́n aláìlẹ́gàn yóò gba ogún rere.

11 Ọlọ́rọ̀ ènìyàn le è gbọ́n lójú ara rẹ̀

ṣùgbọ́n tálákà ó òye ìdí, rẹ̀.

12 Nígbà olódodo ń lékè ariwo ayọ̀ ta;

ṣùgbọ́n nígbà ènìyàn búburú gorí òye, àwọn ènìyàn a na pápá bora.

13 Ẹni ó bo ̀ṣẹ̀ rẹ̀ mọ́lẹ̀ yóò ṣe rere,

ṣùgbọ́n ẹni ó jẹ́wọ́ ó kọ̀ wọ́n sílẹ̀ máa ń àánú gbà.

14 Ìbùkún ni fún ènìyàn náà ó bẹ̀Ọlọ́run nígbà gbogbo

ṣùgbọ́n ẹni ó ọkàn rẹ̀ le bọ́ sínú wàhálà.

15 kìnnìún ń tàbí Beari ń halẹ̀

ni ènìyàn búburú ń jẹ ọba lórí àwọn aláìlágbára.

16 Ọmọ-aládé ó ṣe aláìmòye púpọ̀ ń ṣe ìwà ìkà púpọ̀ pẹ̀,

ṣùgbọ́n èyí ó kórìíra ojúkòkòrò yóò ọjọ́ rẹ̀ pẹ́.

17 Ẹni ọkàn rẹ̀ balẹ̀ nítorí ̀ṣẹ̀ ìpànìyàn

yóò máa joró rẹ̀ títí ikú

ṣe jẹ́ ẹnikẹ́ni ràn án lọ́wọ́.

18 Ẹni ń rìn déédéé yóò ,

ṣùgbọ́n ẹni ̀rẹ̀ jẹ́ àyídáyidà ni yóò ṣubú lójijì.

19 Ẹni ó ro ilẹ̀ rẹ̀ yóò oúnjẹ lọ́pọ̀lọ́pọ̀

ṣùgbọ́n ẹni ń ohun asán yóò kún fún òsì.

20 Olóòtítọ́ ènìyàn yóò ìbùkún gbà gan an

ṣùgbọ́n ẹni ojú ń kán láti di ọlọ́rọ̀ yóò lọ láìjìyà.

21 Ojúsàájú ṣíṣe dára,

síbẹ̀ ènìyàn kan ń ṣẹ̀ nítorí òkèlè oúnjẹ kan.

22 Ahun ń sáré àti

funra òsì dúró de òun.

23 Ẹni ó ènìyàn kan yóò ojúrere ni nígbẹ̀yìn

ju ẹni ó ètè ̀tàn lọ.

24 Ẹni ó ja baba tàbí ìyá rẹ̀ lólè

ó , "í ṣe ̀ṣẹ̀,"

irú kan ni òun àti ẹni ń pa ni run.

25 ̀kánjúwà ènìyàn a máa ìjà sílẹ̀,

ṣùgbọ́n ẹni ó gbẹ́kẹ̀Olúwa yóò gbilẹ̀.

26 Ẹni ó gbẹ́kẹ̀ara rẹ̀ jẹ́ aláìgbọ́n

ṣùgbọ́n ẹni ń rìn nínú ọgbọ́n láìléwu.

27 Ẹni ó ń fi fún tálákà yóò ṣe aláìní ohunkóhun,

ṣùgbọ́n ẹni ó di ojú rẹ̀ wọn gba ̀pọ̀lọpọ̀ ègún.

28 Nígbà ènìyàn búburú dórí ìjọba, àwọn ènìyàn a na pápá bora;

ṣùgbọ́n nígbà ènìyàn búburú ṣègbé,

àwọn olódodo ń gbilẹ̀ i.

Veja também

Publicidade
Bíblia Online Bíblia Online

Bíblia Online • Versão: 2026-06-28_14-13-17-