Pular para o conteúdo
Publicidade

Resultados da busca por "amor"

70 resultados encontrados

  1. Números 21

    ní oore ọ̀fẹ́ láti lo Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde-Òní
    Capítulo 21
    Mostrando versículos 21–31 de 35

    21 21.21-30: De 2.26-37. Israẹli rán oníṣẹ́ láti sọ fún Sihoni ọba àwọn ará Amori wí pé,

    25Israẹli sì gba gbogbo ìlú Amori wọ́n sì ń gbé ibẹ̀ pẹ̀lú Heṣboni, àti gbogbo ibùgbé ìlú tó yí i ká.

    31Nígbà náà ni àwọn ọmọ Israẹli sì ń gbé ní ilẹ̀ Amori.

  2. Amós 2

    ní oore ọ̀fẹ́ láti lo Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde-Òní
    Capítulo 2
    Mostrando versículos 9–13 de 16

    9"Mo pa àwọn ará Amori run níwájú wọngíga ẹni tí ó dàbí igi kedari.Òun sì le koko bí igi óákùmo pa èso rẹ̀ run láti òkè wáàti egbò rẹ̀ láti ìsàlẹ̀ wá.

    10Èmi mú un yín gòkè láti ilẹ̀ Ejibiti wá,mo sì sìn yín la aginjù já ní ogójì ọdúnláti fi ilẹ̀ àwọn ará Amori fún un yín.

    13"Ní báyìí, èmi yóò tẹ̀ yín mọ́lẹ̀bí kẹ̀kẹ́ tí ó kún fún ìtí ti í tẹ̀.

  3. Salmos 135

    ní oore ọ̀fẹ́ láti lo Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde-Òní
    Capítulo 135
    Mostrando versículos 1–15 de 21

    1Ẹ yin Olúwa.Ẹ yin orúkọ Olúwa;ẹ yìn ín, ẹ̀yin ìránṣẹ́ Olúwa.

    8Ẹni tí ó kọlu àwọn àkọ́bí Ejibiti,àti ti ènìyàn àti ti ẹranko.

    15Fàdákà òun wúrà ni èrè àwọn aláìkọlà,iṣẹ́ ọwọ́ ènìyàn ni.

  4. Juízes 10

    ní oore ọ̀fẹ́ láti lo Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde-Òní
    Capítulo 10
    Mostrando versículos 5–11 de 18

    5Nígbà tí Jairi kú wọ́n sin ín sí Kamoni.

    7ó bínú sí wọn, ó fi wọ́n sílẹ̀ fún àwọn ará Filistini àti Ammoni láti jẹ ẹ́ ní ìyà.

    11Olúwa sì dáhùn pé, "Ǹjẹ́ nígbà tí àwọn ará Ejibiti, Amori, Ammoni, Filistini,

  5. Gênesis 15

    ní oore ọ̀fẹ́ láti lo Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde-Òní
    Capítulo 15
    Mostrando versículos 6–21 de 21

    6 15.6: Ro 4.3; Ga 3.6; Jk 2.23. Abramu gba Olúwa gbọ́, a sì kà á sí òdodo fún un.

    20àti ti ará Hiti, àti ti ará Peresi, àti ti ará Refaimu.

    21Àti ti ará Amori, àti ti ará Kenaani, àti ti ará Girgaṣi àti ti ará Jebusi."

  6. Josué 13

    ní oore ọ̀fẹ́ láti lo Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde-Òní
    Capítulo 13
    Mostrando versículos 4–20 de 33

    4láti gúúsù;gbogbo ilẹ̀ àwọn ará Kenaani, láti Arah ti àwọn ará Sidoni títí ó fi dé Afeki, agbègbè àwọn ará Amori,

    19Kiriataimu, Sibma, Sereti Ṣahari lórí òkè ní àfonífojì.

    20Beti-Peori, gẹ̀rẹ́gẹ̀rẹ́ Pisga, àti Beti-Jeṣimoti

  7. Deuteronômio 3

    ní oore ọ̀fẹ́ láti lo Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde-Òní
    Capítulo 3
    Mostrando versículos 7–29 de 29

    7Ṣùgbọ́n a kó gbogbo ohun ọ̀sìn àti ìkógun àwọn ìlú wọn, fún ara wa.

    9(Àwọn ará Sidoni ń pe Hermoni ní Sirioni. Àwọn Amori sì ń pè é ní Seniri).

    29Báyìí ni a dúró ní àfonífojì ní ẹ̀bá Beti-Peori.

  8. 1 Samuel 7

    ní oore ọ̀fẹ́ láti lo Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde-Òní
    Capítulo 7
    Mostrando versículos 9–15 de 17

    9Nígbà náà ni Samuẹli mú ọ̀dọ́-àgùntàn tí ó jẹ́ ọmọ ọmú, ó sì fi rú ẹbọ sísun sí Olúwa. Ó sí ké pe Olúwa nítorí ilé Israẹli, Olúwa sì dá a lóhùn.

    15Samuẹli tẹ̀síwájú gẹ́gẹ́ bí adájọ́ lórí Israẹli. Ní ọjọ́ ayé e rẹ̀.

  9. 2 Crônicas 8

    ní oore ọ̀fẹ́ láti lo Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde-Òní
    Capítulo 8
    Mostrando versículos 3–13 de 18

    3Nígbà náà Solomoni lọ sí Hamati-Ṣoba ó sì borí rẹ̀.

    12Lórí pẹpẹ Olúwa tí ó ti kọ́ níwájú ìloro náà, Solomoni sì rú ẹbọ sísun sí Olúwa,

    13nípa ìlànà ojoojúmọ́ fún ẹbọ rírú tí a pàṣẹ láti ọ̀dọ̀ Mose wá fún ọjọ́ ìsinmi, oṣù tuntun àti lẹ́rìn mẹ́ta lọ́dún, ní àjọ àìwúkàrà, ní àjọ ọ̀sẹ̀ méje àti àjọ àgọ́.

  10. Deuteronômio 1

    ní oore ọ̀fẹ́ láti lo Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde-Òní
    Capítulo 1
    Mostrando versículos 10–27 de 46

    10Olúwa Ọlọ́run yín ti sọ yín di púpọ̀ lónìí, ẹ̀yin sì ti pọ̀ bí ìràwọ̀ ní ojú ọ̀run.

    20Nígbà náà ni mo sọ fún un yín pé, "Ẹ ti dé ilẹ̀ òkè àwọn ará Amori, èyí tí Olúwa Ọlọ́run wa fún wa.

    27Ẹ kùn nínú àgọ́ ọ yín, ẹ sì wí pé, "Olúwa kórìíra wa, torí èyí ló fi mú wa jáde láti Ejibiti láti fi wá lé àwọn ará Amori lọ́wọ́ láti pa wá run.

  11. Êxodo 3

    ní oore ọ̀fẹ́ láti lo Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde-Òní
    Capítulo 3
    Mostrando versículos 2–6 de 22

    23.2: Ap 7.30.Níbẹ̀ ni angẹli Olúwa ti yọ sí i nínú ọ̀wọ́-iná tí ń jó láàrín igbó. Mose rí i pé iná ń jó nínú igbó ṣùgbọ́n igbó kò run.

    4Nígbà tí Olúwa rí i pe Mose ti lọ láti lọ wò ó, Ọlọ́run ké pè é láti àárín igbó náà, "Mose! Mose!"Mose sì dáhùn ó wí pé, "Èmi nìyìí."

    63.6: Mt 22.32; Mk 12.26; Lk 20.37; Ap 3.13; 7.32.Nígbà náà ní ó wí pé, "Èmi ni Ọlọ́run baba rẹ, Ọlọ́run Abrahamu, Ọlọ́run Isaaki àti Ọlọ́run Jakọbu." Nítorí ìdí èyí, Mose sì pa ojú rẹ̀ mọ́, nítorí ó bẹ̀rù láti bojú wo Ọlọ́run.

  12. Juízes 1

    ní oore ọ̀fẹ́ láti lo Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde-Òní
    Capítulo 1
    Mostrando versículos 34–36 de 36

    34Àwọn ará Amori fi agbára dá àwọn ẹ̀yà Dani dúró sí àwọn ìlú orí òkè, wọn kò sì jẹ́ kí wọn sọ̀kalẹ̀ wá sí pẹ̀tẹ́lẹ̀.

    35Àwọn ará Amori ti pinnu láti dúró lórí òkè Heresi àti òkè Aijaloni àti ti Ṣaalbimu, ṣùgbọ́n nígbà tí ẹ̀yà Josẹfu di alágbára wọ́n borí Amori wọ́n sì mú wọn sìn.

    36Ààlà àwọn ará Amori sì bẹ̀rẹ̀ láti ìgòkè Akrabbimu kọjá lọ sí Sela àti síwájú sí i.

  13. Provérbios 17

    ní oore ọ̀fẹ́ láti lo Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde-Òní
    Capítulo 17
    Mostrando versículos 10–17 de 28

    10Ọ̀rọ̀ ìbáwí dun olóye ènìyànju ọgọ́rùn-ún pàṣán lọ lẹ́yìn òmùgọ̀.

    11Orí kunkun ni ènìyàn ìkà máa ń ṣe,ìjòyè aláìláàánú ni a ó rán sí i.

    17Ọ̀rẹ́ a máa fẹ́ni nígbà gbogbo,arákùnrin sì wà fún ìgbà ìpọ́njú.

  14. Cânticos 7

    ní oore ọ̀fẹ́ láti lo Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde-Òní
    Capítulo 7
    Mostrando versículos 3–10 de 13

    3Ọmú rẹ rí bí abo egbin méjìtí wọ́n jẹ́ ìbejì àgbọ̀nrín.

    6Báwo ni ẹwà rẹ ti pọ̀ tóbáwo ni o sì ti dára tó ìwọ olùfẹ́ mi nínú ìfẹ́?

    10Ti olùfẹ́ mi ni èmi í ṣe,èmi sì ni ẹni tí ó wù ú.

  15. Números 13

    ní oore ọ̀fẹ́ láti lo Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde-Òní
    Capítulo 13
    Mostrando versículos 12–15 de 33

    12láti inú ẹ̀yà Dani, Ammieli ọmọ Gemalli;

    13láti inú ẹ̀yà Aṣeri, Seturu ọmọ Mikaeli.

    15láti inú ẹ̀yà Gadi, Geueli ọmọ Maki.

  16. 1 Reis 4

    ní oore ọ̀fẹ́ láti lo Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde-Òní
    Capítulo 4
    Mostrando versículos 8–16 de 34

    8Orúkọ wọn ni wọ̀nyí:Bene-Huri ní ìlú olókè Efraimu.

    14Ahinadabu ọmọ Iddo ní Mahanaimu

    16Baana ọmọ Huṣai ní Aṣeri àti ní Aloti;

  17. Êxodo 33

    ní oore ọ̀fẹ́ láti lo Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde-Òní
    Capítulo 33
    Mostrando versículos 2–17 de 23

    2Èmi yóò rán angẹli ṣáájú yín, Èmi yóò sì lé àwọn Kenaani, àwọn ará Amori, àwọn ará Hiti, àwọn ará Peresi, àwọn ará Hifi àti àwọn ará Jebusi jáde.

    16Báwo ni ẹnikẹ́ni yóò ṣe mọ̀ pé inú rẹ dùn pẹ̀lú mi àti pẹ̀lú àwọn ènìyàn rẹ àyàfi ti o bá bá wa lọ? Kí ni yóò lè yà mí àti àwọn ènìyàn rẹ kúrò lára gbogbo ènìyàn tí ó wà ní ayé?"

    17Olúwa sì sọ fún Mose pé, "Èmi yóò ṣe ohun gbogbo tí ìwọ ti béèrè, nítorí inú mi dún sí o, Èmi sì mọ̀ ọ́n nípa orúkọ rẹ̀."

  18. Esdras 9

    ní oore ọ̀fẹ́ láti lo Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde-Òní
    Capítulo 9
    Mostrando versículos 12–14 de 15

    12Nítorí náà, ẹ má ṣe fi àwọn ọmọbìnrin yín fún àwọn ọmọkùnrin wọn ní ìyàwó tàbí kí ẹ fẹ́ àwọn ọmọbìnrin wọn fún àwọn ọmọkùnrin yín ní ìyàwó. Ẹ má ṣe dá májẹ̀mú àlàáfíà pẹ̀lú wọn nígbàkígbà kí ẹ̀yin kí ó sì le lágbára, kí ẹ sì le máa jẹ ire ilẹ̀ náà, kí ẹ sì le fi í sílẹ̀ fún àwọn ọmọ yín gẹ́gẹ́ bí ogún ayérayé.’

    14Ǹjẹ́ ó yẹ kí àwa tún yẹ̀ kúrò nínú àṣẹ rẹ, kí a sì máa ṣe ìgbéyàwó papọ̀ pẹ̀lú àwọn ènìyàn tí wọn ti ṣe onírúurú ohun ìríra báyìí? Ṣe ìwọ kò ní bínú sí wa láti pa wá run tí kì yóò sẹ́ ku ẹnikẹ́ni tí yóò là?

  19. 2 Samuel 21

    ní oore ọ̀fẹ́ láti lo Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde-Òní
    Capítulo 21
    Mostrando versículo 20 de 22

    20Ìjà kan sì tún wà ní Gati, ọkùnrin kan sì wà tí ó ga púpọ̀, ó sì ní ìka mẹ́fà ní ọwọ́ kan, àti ọmọ ẹsẹ̀ mẹ́fà ní ẹsẹ̀ kan, àpapọ̀ rẹ̀ sì jẹ́ mẹ́rìnlélógún; a sì bí òun náà ní Rafa.

  20. 2 Reis 21

    ní oore ọ̀fẹ́ láti lo Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde-Òní
    Capítulo 21
    Mostrando versículos 10–23 de 26

    10Olúwa sì wí nípasẹ̀ ìránṣẹ́ rẹ̀ wòlíì pé,

    13Èmi yóò sì nà okùn ìwọ̀n kan tí a lò lórí Jerusalẹmu àti lórí Samaria àti òjé ìdiwọ̀n ti a lò lórí ilé Ahabu. Èmi yóò sì nu Jerusalẹmu gẹ́gẹ́ bí ọkàn tí ń nu àwokòtò nù tí o ń nù un tí o sì ń dorí rẹ̀ kodò.

    23Àwọn ìránṣẹ́ Amoni dìtẹ̀ lórí rẹ̀ wọ́n sì lu ọba pa ní àárín ilé rẹ̀.

Léxico (correspondência exata) Semântico (correspondência relacionada) Versículos omitidos Contexto do capítulo