Publicidade

Deuteronômio 1

Àṣẹ láti jáde kúrò Horebu

1 Wọ̀nyí ni àwọn ̀rọ̀ Mose sọ fún gbogbo Israẹli aginjù, aginjù ìlà-oòrùn Jordani, ni Arabah, òdìkejì Ṣufi, àárín Parani àti Tofeli, Labani, Haserotu àti Disahabu. 2 (Ọjọ́ mọ́kànlá ni ó gbà láti rin ìrìnàjò láti Horebu Kadeṣi-Barnea, a gba ̀òkè Seiri.)

3 ìgbà ó ogójì ọdún, ọjọ́ kìn-ín-ní oṣù kọ́kànlá, Mose sọ ohun gbogbo Olúwa pàṣẹ nípa àwọn ọmọ Israẹli fún wọn. 4 Èyí ṣẹlẹ̀ lẹ́yìn ìgbà ó ti ṣẹ́gun Sihoni ọba àwọn Amori, ó jẹ ọba Heṣboni, àti Ogu ọba Baṣani ni ó ṣẹ́gun Edrei, ẹni ó jẹ ọba Aṣtarotu.

5 ìhà ìlà-oòrùn Jordani ó nínú ilẹ̀ Moabu ni Mose bẹ̀rẹ̀ sísọ àsọyé òfin wọ̀nyí :

6 Olúwa Ọlọ́run wa wa sọ̀rọ̀ Horebu , "ti dúró orí òkè yìí pẹ́ . 7 yípadà tẹ̀síwájú ìrìnàjò yín lọ ilẹ̀ òkè àwọn ará Amori, tọ gbogbo àwọn ènìyàn ó ń gbé Arabah lọ aginjù, àwọn orí òkè àti pẹ̀tẹ́lẹ̀, gúúsù àti etí Òkun, lọ ilẹ̀ àwọn ará Kenaani àti lọ Lebanoni, títí fi odò ńlá Eufurate. 8 ó, èmi fi ilẹ̀ fún un yín, wọ inú rẹ̀ lọ gba ilẹ̀ náà Olúwa ti búra òun yóò fún àwọn baba yín: fún Abrahamu, Isaaki, àti Jakọbu, àti fún àwọn àrọ́mọdọ́mọ wọn."

Yíyan àwọn olórí

9 Mo fún un yín nígbà náà , "Èmi nìkan ẹrù u yín gbé. 10 Olúwa Ọlọ́run yín ti sọ yín di púpọ̀ lónìí, ̀yin ti pọ̀ ìràwọ̀ ojú ̀run. 11 Olúwa Ọlọ́run àwọn baba yín sọ yín di púpọ̀ ̀ẹgbẹ̀rún (1,000) i, ó bùkún un yín gẹ́gẹ́ ó ti ṣèlérí. 12 Báwo ni èmi nìkan ṣe máa ru àjàgà àti ìṣòro yín àti èdè-àìyedè yín? 13 yan àwọn ọlọ́gbọ́n, olóye àti àwọn ẹni àpọ́nlé, láti inú ̀yín kọ̀̀kan, èmi yóò fi wọ́n ṣe olórí yín."

14 ̀yin mi lóhùn , "Ohun ìwọ ti gbèrò láti ṣe dára."

15 Bẹ́̀ ni mo yan olórí àwọn ̀yín, àwọn ọlọ́gbọ́n ọkùnrin, ẹni àpọ́nlé, mo fi jẹ olórí yín, olórí ẹgbẹẹ̀rún, olórí ̀rọ̀̀rún, olórí àràádọ́ta, àti olórí mẹ́wàá mẹ́wàá gẹ́gẹ́ àwọn ̀yín. 16 Mo kìlọ̀ fún àwọn onídàájọ́ yín nígbà náà , gbọ́ èdè-àìyedè ó láàrín àwọn ènìyàn an yín ṣe ìdájọ́ òdodo, bóyá ẹjọ́ ó ṣẹlẹ̀ láàrín Israẹli Israẹli ni tàbí láàrín Israẹli kan àlejò. 17 ṣe ojúsàájú ìdájọ́. ṣe ìdájọ́ ẹni ńlá àti kékeré bákan náà. ṣe bẹ̀ẹnikẹ́ni torí ti Ọlọ́run ni ìdájọ́. Ẹjọ́ ó le fún un yín ni fún mi. Èmi yóò gbọ́ . 18 Nígbà náà ni èmi yóò sọ ohun ó ṣe fún un yín.

A rán àwọn Ayọ́lẹ̀jáde

19 Nígbà náà a gbéra láti Horebu, Olúwa Ọlọ́run wa ti pàṣẹ fún , a la àwọn ilẹ̀ lókè Amori kọjá lọ gbogbo aginjù ńlá ó ba ni lẹ́̀yin ti , bẹ́̀ ni a Kadeṣi-Barnea. 20 Nígbà náà ni mo sọ fún un yín , "ti ilẹ̀ òkè àwọn ará Amori, èyí Olúwa Ọlọ́run wa fún wa. 21 kíyèsi i, Olúwa Ọlọ́run yín ni ilẹ̀ náà. lọ gba ilẹ̀ náà Olúwa Ọlọ́run àwọn baba yín sọ fún un yín. bẹ̀, ṣe fòyà."

22 Nígbà náà ni gbogbo yín tọ̀ , "Jẹ́ a yan àwọn ayọ́lẹ̀láti yọ́ ilẹ̀ náà fún wa, wọn fún wa ìròyìn àwọn ̀a ó gbà àti àwọn ìlú a ó pàdé."

23 Èrò náà dára lójú mi, torí èyí ni mo ṣe yan àwọn ènìyàn méjìlá nínú yín, ẹnìkan láti inú ̀kọ̀̀kan. 24 Wọ́n gòkè lọ ilẹ̀ òkè náà, wọ́n àfonífojì Eṣkolu, wọ́n yẹ̀ ́ . 25 Wọ́n lára èso ilẹ̀ náà fún wa , "Ilẹ̀ ó dára ni Olúwa Ọlọ́run wa fún wa."

Ìṣọ̀tẹ̀ Olúwa

26 Ṣùgbọ́n ̀yin fẹ́ gòkè lọ; ṣọ̀tẹ̀ àṣẹ Olúwa Ọlọ́run yín. 27 kùn nínú àgọ́ yín, , "Olúwa kórìíra wa, torí èyí fi wa jáde láti Ejibiti láti fi àwọn ará Amori lọ́wọ́ láti pa run. 28 Níbo la ó lọ? Àwọn arákùnrin wa ti ìrẹ̀wẹ̀wa nípa sísọ , Àwọn ènìyàn náà lágbára wọ́n ga lọ; àwọn ìlú náà tóbi jọjọ bẹ́̀ ni odi wọn ga kan ̀run. A tilẹ̀ àwọn òmíràn (ìran Anaki) níbẹ̀.’ "

29 Nígbà náà ni mo sọ fún un yín , "ṣojo, gbọdọ̀ bẹ̀wọn. 30 Olúwa Ọlọ́run yín, ń ṣáájú yín yóò fún un yín; ó ti ṣe fún un yín Ejibiti lójú ̀yin tìkára yín 31 àti aginjù. Níbẹ̀ ni ti i Olúwa Ọlọ́run yín ti gbé yín, baba ti í gbé ọmọ rẹ̀, gbogbo ̀lọ títí fi padà ibí yìí."

32 Pẹ̀gbogbo èyí mo , gbẹ́kẹ̀Olúwa Ọlọ́run yín, 33 ń ṣáájú u yín lọ gbogbo ̀yín, nípa fífi iná ṣe amọ̀yín òru àti ìkùùkuu ̀sán, láti fi àwọn ibi tẹ̀hàn yín àti àwọn ̀ó rìn.

34 Nígbà Olúwa gbọ́ ohun sọ, inú i, ó búra , 35 "̀kan nínú ìran búburú yìí yóò ilẹ̀ rere mo ti búra láti fún àwọn baba ńlá a yín. 36 ṣe Kalebu ọmọ Jefunne. Òun ni yóò wọ̀ ́. Èmi yóò fún òun àti àwọn ìran rẹ̀ ilẹ̀ náà ó ti fi ẹsẹ̀ rẹ̀ tẹ̀; torí ó fi gbogbo ọkàn rẹ̀ tẹ̀Olúwa."

37 Torí i tiyín ni Olúwa fi bínú mi , "Ìwọ náà yóò wọ ibẹ̀ bákan náà, 38 ṣùgbọ́n Joṣua ọmọ Nuni ń ṣe olùrànlọ́wọ́ rẹ ni yóò wọ ibẹ̀. un, ọkàn le torí , òun yóò ṣáájú àwọn ọmọ Israẹli láti gba ilẹ̀ náà. 39 Àwọn èwe yín sọ wọn yóò lẹ́. Àwọn ọmọ yín ko ì mọ rere yàtọ̀ búburú ni yóò wọ ilẹ̀ náà. 40 Ṣùgbọ́n ̀yin, padà aginjù ó ̀ó lọ Òkun Pupa."

41 Nígbà náà ni fèsì , "Àwa ti ṣẹ̀ Olúwa. A ó gòkè lọ láti , gẹ́gẹ́ Olúwa Ọlọ́run wa ti pàṣẹ fún wa." Torí náà gbogbo yín ohun ìjà a yín, ó rọrùn láti gòkè lọ àwọn orílẹ̀-èdè olókè náà.

42 Ṣùgbọ́n Olúwa sọ fún mi , "Sọ fún wọn, ṣe gòkè lọ láti torí èmi yóò pẹ̀u yín. Àwọn ̀a yín yóò ṣẹ́gun yín.’ "

43 Bẹ́̀ ni mo sọ fún yín, ̀yin gbọ́, ̀yin ṣọ̀tẹ̀ òfin Olúwa, pẹ̀ìgbéraga yín, gòkè lọ ìlú olókè náà. 44 Àwọn ará Amori ń gbé àwọn òkè náà, dojúkọ yín àgbájọpọ̀ oyin. Wọ́n yín bolẹ̀ láti Seiri títí Horma. 45 padà, sọkún níwájú Olúwa, òun fetí igbe ẹkún yín, Ó kọ etí dídi i yín. 46 Báyìí ni dúró Kadeṣi fún ̀pọ̀lọpọ̀ ọjọ́ gẹ́gẹ́ ̀yin ti ṣe.

Veja também

Publicidade
Bíblia Online Bíblia Online

Bíblia Online • Versão: 2026-06-29_22-07-56-