Pular para o conteúdo
Publicidade

Deuteronômio 11

Fẹ́ràn Olúwa o gbọ́ tirẹ̀

1 fẹ́ràn Olúwa Ọlọ́run yín, pa ìfẹ́ rẹ̀, ìlànà rẹ̀, òfin rẹ̀ àti àṣẹ rẹ̀ mọ́ ìgbà gbogbo. 2 rántí lónìí , í ṣe àwọn ọmọ yín, ni ó ìbáwí Olúwa Ọlọ́run yín; títóbi rẹ̀, ọwọ́ agbára rẹ̀, nína ọwọ́ rẹ̀; 3 iṣẹ́ àmì rẹ̀ àti ohun ó ṣe àárín àwọn ará Ejibiti, Farao ọba Ejibiti àti gbogbo orílẹ̀-èdè rẹ̀. 4 Ohun ó ṣe àwọn jagunjagun Ejibiti, kẹ̀kẹ́ ogun àti ẹlẹ́ṣin rẹ̀: ó ṣe wọ́n sínú Òkun Pupa, wọ́n ṣe ń e yín Olúwa fi pa wọ́n run pátápátá títí di òní olónìí yìí. 5 í ṣe àwọn ọmọ yín ni ó ohun ó ṣe fún un yín aginjù, títí fi ìhín yìí, 6 11.6: Nu 16.31,32.ohun ó ṣe Datani àti Abiramu, àwọn ọmọ Eliabu, ̀Reubeni, ilẹ̀ ti lanu ojú gbogbo ará Israẹli ó gbé wọn pẹ̀gbogbo ìdílé wọn, gbogbo àgọ́ wọn àti gbogbo ohun alààyè ó jẹ́ tiwọn. 7 Ṣùgbọ́n ojú u yín gan an ni ó gbogbo nǹkan ńlá wọ̀nyí Olúwa ti ṣe.

8 Nítorí náà, kíyèsi gbogbo àṣẹ mo ń fún yín lónìí, ba à lágbára àti lọ, gba ilẹ̀ náà ó la Jordani kọjá lọ. 9 ba à pẹ́ orí ilẹ̀ Olúwa ti búra fún àwọn baba ńlá a yín, láti fún àwọn àti àwọn ọmọ wọn: ilẹ̀ ó ń sàn fún wàrà àti oyin. 10 Ilẹ̀ ̀ ń wọ̀ lọ láti gbà ilẹ̀ Ejibiti, níbi ti , níbi jẹ́ ẹsẹ̀ yín ni fi ń rìn lọ bomirin irúgbìn gbìn oko ̀fọ́. 11 Ṣùgbọ́n ilẹ̀ ó la Jordani kọjá láti gbà, jẹ́ ilẹ̀ olókè àti pẹ̀tẹ́lẹ̀ òjò ń rọ̀ latọ̀run. 12 Ilẹ̀ Olúwa Ọlọ́run yín ń mójútó ni, ojú Olúwa Ọlọ́run yín ń fi ìgbà gbogbo lórí rẹ̀, láti ìbẹ̀rẹ̀ ọdún òpin ọdún.

13 11.13-17: Le 26.3-5; De 7.12-16; 28.1-14. Nítorí náà, gbọ́rọ̀ àṣẹ mo fún un yín lónìí tọkàntọkàn: fẹ́ràn Olúwa Ọlọ́run yín, sìn ín, pẹ̀gbogbo àyà yín àti gbogbo ọkàn yín: 14 nígbà náà, èmi yóò rọ òjò sórí ilẹ̀ yín lákòókò rẹ̀, àti òjò àkọ́rọ̀ àti ti àrọ̀kẹ́yìn, ba à kórè oúnjẹ yín wọlé àní wáìnì tuntun àti òróró. 15 Èmi yóò koríko lórí ilẹ̀ yín fún àwọn ohun ̀sìn in yín, ó jẹ, ó .

16 ṣọ́ra, a ba à tàn yín jẹ láti yípadà sin ọlọ́run mìíràn àti láti máa foríbalẹ̀ fún wọn. 17 Nígbà náà ni ìbínú Olúwa yóò ru i yín, Òun yóò ti ìlẹ̀kùn ̀run òjò ba à rọ̀, ilẹ̀ yóò so èso kankan, ó ṣègbé ilẹ̀ rere Olúwa fi fún un yín. 18 fi gbogbo ̀rọ̀ mi wọ̀nyí àyà a yín, àti ọkàn an yín, so wọ́n àmì sórí ọwọ́ yín, so wọ́n mọ́ iwájú orí yín. 19 máa fi wọ́n kọ́ àwọn ọmọ yín, máa sọ̀rọ̀ nípa wọn jókòó nínú ilé, àti ojú ̀ń rìn lọ, sùn àti . 20 ìwọ ó kọ wọ́n sára òpó ilé rẹ̀, àti ara ìlẹ̀kùn ̀òde rẹ. 21 ọjọ́ yín àti ti àwọn ọmọ yín pọ̀ ilẹ̀ Olúwa ti búra láti fi fún àwọn baba ńlá a yín, ìwọ̀n ìgbà ̀run lókè ayé ń bẹ ìsàlẹ̀.

22 fi ara balẹ̀ kíyèsi àwọn òfin mo ń fún un yín, láti tẹ̀, láti fẹ́ Olúwa Ọlọ́run yín, láti máa rìn gbogbo ̀rẹ̀ àti láti dìímú ṣinṣin: 23 Olúwa yóò gbogbo orílẹ̀-èdè wọ̀nyí kúrò níwájú u yín. ó gba orílẹ̀-èdè ó lágbára ó tóbi yín lọ. 24 Gbogbo ibi fi ẹsẹ̀ yín tẹ̀ ni yóò jẹ́ tiyín, ilẹ̀ yín yóò gbilẹ̀ láti aginjù Lebanoni, àti láti odò Eufurate Òkun Ńlá. 25 ẹni náà yóò yín lójú ìjà, Olúwa Ọlọ́run yín yóò fi ̀àti ìwárìrì i yín sórí gbogbo ilẹ̀ náà ó ti ṣèlérí fún un yín gbogbo ibi lọ.

26 kíyèsi i, mo fi ìbùkún àti ègún lélẹ̀ níwájú u yín lónìí: 27 ìbùkún ni, pa òfin Olúwa Ọlọ́run yín, mo ń fún un yín lónìí mọ́. 28 Ègún ni, ṣàìgbọ́ràn, òfin Olúwa Ọlọ́run yín, yapa kúrò ̀mo ti sílẹ̀ fún yín lónìí, nípa títẹ̀ọlọ́run mìíràn, ì mọ̀. 29 Nígbà Olúwa Ọlọ́run yín ti un yín ilẹ̀ náà ń wọ̀ láti gbà, kéde àwọn ìbùkún náà orí òkè Gerisimu, kéde àwọn ègún orí òkè Ebali. 30 ti mọ̀ àwọn òkè wọ̀nyí ìkọjá a Jordani apá ìwọ̀-oòrùn lójú ̀lọ ìhà ìlà-oòrùn, ̀gbẹ́ igi ńlá igbó More, ilẹ̀ àwọn ará a Kenaani, wọ́n ń gbé aginjù, ni agbègbè Gilgali. 31 ti ṣetán láti la Jordani kọjá láti gba ilẹ̀ náà Olúwa Ọlọ́run yín ń fún un yín. Nígbà gbà á, ń gbé ibẹ̀, 32 i dájú ̀ ń gbọ́rọ̀ gbogbo ìlànà àti òfin mo ń gbé kalẹ̀ fún un yín lónìí.

Veja também