Publicidade

Deuteronômio 12

Ibi ìsìn kan ṣoṣo

1 12.1-28: El 20.24. Wọ̀nyí ni àwọn ìlànà àti òfin gbọdọ̀ ṣọ́ra láti máa tẹ̀, ilẹ̀ Olúwa Ọlọ́run àwọn baba yín, fi fún un yín láti gbà: gbogbo ìgbà fi lórí ilẹ̀ náà. 2 Gbogbo ibi gíga àwọn òkè ńlá, àti òkè kéékèèké àti lábẹ́ gbogbo igi ń gbilẹ̀ níbi àwọn orílẹ̀-èdè ó jáde, ń sin òrìṣà wọn kúrò pátápátá. 3 àwọn pẹpẹ wọn, bi òpó ìsìn wọn ṣubú, sun òpó Aṣerah wọn iná. gbogbo ère òrìṣà wọn lulẹ̀, pa orúkọ wọn rẹ́ gbogbo ààyè wọn.

4 gbọdọ̀ sin Olúwa Ọlọ́run yín i tiwọn. 5 Ṣùgbọ́n ibi Olúwa Ọlọ́run yín yóò yàn láàrín àwọn ̀yín, láti fi orúkọ rẹ̀ síbẹ̀ i ibùgbé rẹ̀. Ibẹ̀ ni lọ. 6 Níbẹ̀ ni ẹbọ sísun àti ẹbọ yín , ìdámẹ́wàá yín àti ọrẹ àkànṣe, àwọn ̀jẹ́ yín, ọrẹ àtinúwá yín, àti àwọn àkọ́gbogbo màlúù yín àti ewúrẹ́ yín. 7 Níwájú Olúwa Ọlọ́run yín níbẹ̀, ̀yin àti ìdílé yín jẹun , nínú gbogbo ìdáwọ́e yín, torí Olúwa Ọlọ́run yín ti bùkún un yín.

8 ̀yin ó ṣe ṣe gẹ́gẹ́ a ṣe níhìn-ín lónìí yìí, olúkúlùkù ń ṣe ohun ó tọ́ ojú ara rẹ̀. 9 Níwọ́n ìgbà ti ibi ìsinmi, àti ibi ogún Olúwa Ọlọ́run yín fún un yín. 10 Ṣùgbọ́n ó la Jordani kọjá, ó máa gbé ilẹ̀ Olúwa Ọlọ́run yín fún un yín ìní, yóò fún un yín ìsinmi, kúrò láàrín àwọn ̀a yín, ó i yín , ba à máa gbé láìléwu. 11 Níbi Olúwa Ọlọ́run yín yóò yàn ibùgbé fún orúkọ rẹ̀. Níbẹ̀ ni gbogbo ohun mo pàṣẹ fún un yín : àwọn ọrẹ yín àti àwọn ẹbọ sísun, ìdámẹ́wàá yín àti ọrẹ àkànṣe, àti gbogbo ohun ìní yín ti yàn, èyí ti jẹ́ ̀jẹ́ fún Olúwa. 12 máa yọ̀ níwájú Olúwa Ọlọ́run yín níbẹ̀, ̀yin, àwọn ọmọkùnrin yín, àwọn ọmọbìnrin yín, ìránṣẹ́bìnrin àti ìránṣẹ́kùnrin yín, àti àwọn Lefi láti ìlú u yín, wọn ìpín tàbí ogún tiwọn. 13 ṣọ́ra ṣe ẹbọ sísun yín ibikíbi ̀yin fẹ́. 14 Ibi Olúwa yóò yàn láàrín àwọn ̀a yín nìkan ni ti máa ẹbọ sísun yín, máa kíyèsi ohun gbogbo mo pàṣẹ fún un yín níbẹ̀.

15 Síbẹ̀síbẹ̀, lọ pa àwọn ẹran yín èyíkéyìí nínú àwọn ìlú u yín, jẹ ẹran náà ti fẹ́, ti ń ṣe àgbọ̀nrín àti èsúró, gẹ́gẹ́ ìbùkún Olúwa Ọlọ́run yín ó fi fún un yín, àti ẹni mímọ́ àti aláìmọ́ ni ó jẹ nínú àwọn ẹran náà. 16 12.16,23: Le 17.10-14; 19.26.Ṣùgbọ́n gbọdọ̀ jẹ ̀jẹ̀ wọn, á sílẹ̀ omi. 17 gbọdọ̀ jẹ ìdámẹ́wàá oúnjẹ yín, wáìnì tuntun, òróró, àkọ́àwọn màlúù yín, tàbí ti ewúrẹ́ yín, ohunkóhun ó jẹ́ ̀jẹ́, ọrẹ àtinúwá, tàbí ̀bùn pàtàkì ìlú ̀yin tìkára yín. 18 ṣe jẹ ́ níwájú Olúwa Ọlọ́run yín, níbi Olúwa Ọlọ́run yín, yóò yàn: ìwọ, àwọn ọmọkùnrin rẹ, àwọn ọmọbìnrin rẹ, àwọn ìránṣẹ́kùnrin àti ìránṣẹ́bìnrin rẹ àti àwọn ọmọ Lefi láti ìlú u yín, máa yọ̀ níwájú Olúwa Ọlọ́run yín, nínú gbogbo ìdáwọ́e yín. 19 ṣọ́ra ṣe gbàgbé àwọn Lefi, gbogbo ìgbà ń gbé ilẹ̀ yín.

20 Olúwa Ọlọ́run yín ti fẹ́ agbègbè e yín ó ti ṣe ìlérí, fún un yín, , àwa yóò jẹ ẹran, nítorí ọkàn wa fẹ́ jẹran. jẹ ẹran náà fẹ́. 21 ibi Olúwa Ọlọ́run yín yàn fún orúkọ rẹ̀ jìnnà i yín, pa màlúù tàbí ewúrẹ́ Olúwa Ọlọ́run yín fún un yín, mo ti pàṣẹ fún un yín ìlú u yín, jẹ ́ ti fẹ́. 22 jẹ wọ́n ó ti jẹ èsúró tàbí àgbọ̀nrín, ẹni a mímọ́ àti aláìmọ́ ni ó jẹ ́. 23 Ṣùgbọ́n i dájú jẹ ̀jẹ̀ wọn, nítorí ̀jẹ̀ ni ̀, gbọdọ̀ jẹ ̀pọ̀ mọ́ ẹran. 24 gbọdọ̀ jẹ ̀jẹ̀, á sílẹ̀ omi. 25 ṣe jẹ ́, ó à dára fún ̀yin àti àwọn ọmọ yín, ń bọ̀ lẹ́yìn in yín. Nígbà ń ṣe ohun ó tọ̀lójú Olúwa.

26 àwọn ohun sọ́tọ̀ àti àwọn ̀jẹ́ yín, lọ ibi Olúwa yóò yàn. 27 fi ẹbọ sísun yín kalẹ̀ lórí i pẹpẹ Olúwa Ọlọ́run yín, àti ẹran àti ̀jẹ̀ rẹ̀. ̀jẹ̀ ọrẹ yín ni ki pẹpẹ Olúwa Ọlọ́run yín, ṣùgbọ́n jẹ ẹran. 28 kíyèsára láti máa gbọ́rọ̀ gbogbo ìlànà ń fún un yín, o à dára fún ̀yin àti àwọn ọmọ yín nígbà gbogbo, nítorí nígbà náà ń ṣe ohun ó dára ó tọ̀níwájú Olúwa Ọlọ́run yín.

29 12.29-32: El 23.24; 34.12-14; Nu 33.52. Olúwa Ọlọ́run yín yóò àwọn orílẹ̀-èdè fẹ́ kúrò fẹ́ gba ilẹ̀ wọn kúrò níwájú u yín. Ṣùgbọ́n nígbà ti wọn jáde ń gbé ilẹ̀ wọn. 30 Lẹ́yìn ìgbà a ti pa wọ́n run níwájú u yín, ṣọ́ra ba à bọ́ sínú àdánwò nípa bíbéèrè nípa àwọn òrìṣà wọn , "Báwo ni àwọn orílẹ̀-èdè yìí ṣe ń sin àwọn òrìṣà wọn? Àwa náà yóò ṣe bẹ́̀". 31 gbọdọ̀ sin Olúwa Ọlọ́run yín àwọn, torí , nípa sínsin ọlọ́run wọn, wọ́n ń ṣe ̀pọ̀lọpọ̀ ohun ìríra Ọlọ́run kórìíra. Wọ́n ń dáná sun àwọn ọmọkùnrin àti àwọn ọmọbìnrin wọn láti fi ẹbọ ère òrìṣà wọn.

32 12.32: De 4.2; If 22.18,19. i ̀ ń ṣe gbogbo ohun mo ti pàṣẹ fún un yín. ṣe fi kún un, ṣe yọ kúrò níbẹ̀.

Veja também

Bíblia Online Bíblia Online

Bíblia Online • Versão: 2026-07-04_23-13-58-