Pular para o conteúdo
Publicidade

Deuteronômio 17

18 Nígbà ó jókòó lórí ìtẹ́ ìjọba rẹ̀, ó ṣe àdàkọ àwọn òfin wọ̀nyí inú ìwé fún ara rẹ̀, láti inú ti àlùfáà wọ́n jẹ́ ọmọ Lefi. 19 Èyí yóò lọ́dọ̀ rẹ̀, òun ó máa nínú rẹ̀ gbogbo ọjọ́ ayé rẹ̀, ó máa kọ́ àti bẹ̀Olúwa Ọlọ́run rẹ̀, láti máa tẹ̀gbogbo ̀rọ̀ inú òfin yìí àti àwọn ìlànà rẹ̀ tọkàntọkàn. 20 ó ba à lérò òun sàn ju àwọn arákùnrin rẹ̀ yòókù lọ, ó ti ipa bẹ́̀ yípadà kúrò nínú òfin wọ̀nyí ̀tún tàbí òsì. Bẹ́̀ ni òun àti àwọn ọmọ rẹ̀ yóò jẹ ọba pẹ́ títí Israẹli.

Veja também