Pular para o conteúdo
Publicidade

Deuteronômio 17

1 17.1: Le 22.17-24. ṣe fi màlúù tàbí àgùntàn ó àbùkù, tàbí àbàwọ́n ẹbọ Olúwa Ọlọ́run yín, nítorí ìríra ni èyí yóò jẹ́ fún un.

2 17.2-7: Ek 22.20. ọkùnrin tàbí obìnrin kan ń gbé láàrín yín èyíkéyìí ìlú wọ̀n-ọn-nì, Olúwa fún un yín ń ṣe ibi ojú Olúwa Ọlọ́run yín, ríré májẹ̀rẹ̀ kọjá, 3 èyí ó lòdì òfin mi, ó ń sin ọlọ́run mìíràn, ó ń foríbalẹ̀ fún wọn: àní oòrùn, òṣùpá àti àwọn ìràwọ̀ ojú ̀run, 4 èyí etí ìgbọ́ yín, wádìí ̀rọ̀ náà dájúdájú. ó jẹ́ òtítọ́ ó hàn gbangba ó ti ṣe ohun ìríra yìí, Israẹli. 5 ọkùnrin tàbí obìnrin ó ti ṣe ibi yìí ẹnu-ọ̀ibodè ìlú u yín, sọ ́ òkúta pa. 6 17.6: Nu 35.30; De 19.15; Mt 18.16; 2Kọ 13.1; 1Tm 5.19; Hb 10.28.Lénu ẹlẹ́rìí méjì tàbí mẹ́ta ni a ó pa ọkùnrin náà ó yẹ láti , ṣùgbọ́n ṣe pànìyàn nípasẹ̀ ẹlẹ́rìí kan ṣoṣo. 7 17.7: De 19.19; 1Kọ 5.13.Àwọn ẹlẹ́rìí ni ó kọ́kọ́ gbọ́wọ́ e láti pa á. Lẹ́yìn èyí ni gbogbo ènìyàn dáwọ́jọ láti pa á. Nípa báyìí, ̀yin yóò fọ ohun búburú náà mọ́ kúrò àárín yín.

Àwọn ilé ẹjọ́

8 ẹjọ́ ilé ẹjọ́ èyí ó nira láti , yálà ìtàjẹ̀ sílẹ̀ ni, ̀ràn dídá tàbí ìkanni-lábùkù, wọn lọ ibi Olúwa Ọlọ́run yín yóò yàn. 9 lọ ̀dọ̀ àwọn àlùfáà í ṣe Lefi, àní ̀dọ̀ adájọ́ ó fún ìgbẹ́jọ́ ìgbà náà. béèrè lọ́wọ́ wọn, wọn yóò ṣe ìdájọ́. 10 ìwọ ó ṣe ̀rọ̀ ìdájọ́, ti àwọn ará ibi Olúwa yóò yàn náà yóò fihàn , ìwọ ó máa kíyèsí àti máa ṣe gẹ́gẹ́ bi gbogbo èyí wọn kọ́ . 11 ṣe òfin wọ́n kọ́ yín, àti ìpinnu wọ́n fún un yín. ṣe yípadà sọ́tùn tàbí sósì, kúrò nínú ohun wọ́n sọ fún un yín. 12 Ọkùnrin náà ó ṣe àìbọ̀wọ̀ fún adájọ́ tàbí àlùfáà ó ń ṣe iṣẹ́ ìránṣẹ́ Olúwa Ọlọ́run yín, níbẹ̀ ni pa á. Nípa báyìí ̀yin yóò fọ ohun búburú náà mọ́ kúrò Israẹli. 13 Gbogbo ènìyàn ni yóò gbọ́, ̀yóò wọ́n, wọn ṣe àìgbọ́ràn mọ́.

Ọba

14 Nígbà ilẹ̀ náà Olúwa Ọlọ́run yín yóò fún un yín, ti gba ilẹ̀ náà, ń gbé inú rẹ̀, sọ , "jẹ́ a yan ọba yóò jẹ wa lórí i ti àwọn orílẹ̀-èdè ó wa ." 15 i dájú ọba Olúwa Ọlọ́run yín yàn fún un yín yàn. Ó gbọdọ̀ jẹ́ láàrín àwọn arákùnrin yín. ṣe fi àjèjì jẹ ọba lórí i yín: àní ẹni í ṣe arákùnrin Israẹli. 16 Síwájú i, ọba náà gbọdọ̀ ̀pọ̀lọpọ̀ ẹṣin jọ fún ara rẹ̀, tàbí ó rán àwọn ènìyàn náà padà Ejibiti láti àwọn ẹṣin i, nítorí Olúwa ti sọ fún un yín , "gbọdọ̀ tún padà lọ ̀náà mọ́." 17 gbọdọ̀ aya jọ, ọkàn rẹ̀ a yapa kúrò. gbọdọ̀ fàdákà àti wúrà jọ fún ara rẹ̀ lọ́pọ̀lọ́pọ̀.

18 Nígbà ó jókòó lórí ìtẹ́ ìjọba rẹ̀, ó ṣe àdàkọ àwọn òfin wọ̀nyí inú ìwé fún ara rẹ̀, láti inú ti àlùfáà wọ́n jẹ́ ọmọ Lefi. 19 Èyí yóò lọ́dọ̀ rẹ̀, òun ó máa nínú rẹ̀ gbogbo ọjọ́ ayé rẹ̀, ó máa kọ́ àti bẹ̀Olúwa Ọlọ́run rẹ̀, láti máa tẹ̀gbogbo ̀rọ̀ inú òfin yìí àti àwọn ìlànà rẹ̀ tọkàntọkàn. 20 ó ba à lérò òun sàn ju àwọn arákùnrin rẹ̀ yòókù lọ, ó ti ipa bẹ́̀ yípadà kúrò nínú òfin wọ̀nyí ̀tún tàbí òsì. Bẹ́̀ ni òun àti àwọn ọmọ rẹ̀ yóò jẹ ọba pẹ́ títí Israẹli.

Veja também