Pular para o conteúdo
Publicidade

Deuteronômio 22

Ìrúfin ìgbéyàwó

13 ọkùnrin kan ìyàwó àti, lẹ́yìn ìgbà ó ti dùbúlẹ̀ pẹ̀rẹ̀, kórìíra rẹ̀, 14 ó ṣì sọ̀rọ̀ ìbàjẹ́ i, o fún un orúkọ búburú, , "Mo fẹ́ obìnrin yìí, ṣùgbọ́n nígbà mo súnmọ́ ọn. Èmi àmì ìbálé rẹ̀." 15 Nígbà náà ni baba ọmọbìnrin náà àti ìyá rẹ̀ yóò ̀, ó ti ìbálé tẹ́lẹ̀ ̀dọ̀ àwọn àgbàgbà ìlú ẹnu-bodè. 16 Baba obìnrin náà yóò fún àwọn àgbàgbà , "Mo fi ọmọbìnrin mi fún ọkùnrin yìí láti fẹ́ níyàwó, ṣùgbọ́n ó kórìíra rẹ̀. 17 ìsinsin yìí ó ti sọ̀rọ̀ ìbàjẹ́ i ó , Èmi ọmọbìnrin rẹ ó wúńdíá.Ṣùgbọ́n níhìn-ín yìí ni ̀ìbálé ọmọbìnrin mi." Nígbà náà ni àwọn òbí rẹ̀ yóò fi aṣọ hàn níwájú àwọn àgbàgbà ìlú,

Veja também