Publicidade

Deuteronômio 3

Ìṣẹ́gun Ogu ọba Baṣani

1 Lẹ́yìn èyí a yípadà a kọrí ̀ó lọ Baṣani, Ogu ọba Baṣani àti gbogbo jagunjagun rẹ̀ ṣígun pàdé wa Edrei. 2 Olúwa sọ fún mi , "ṣe bẹ̀rẹ̀, nítorí fi òun lọ́wọ́, àti àwọn ọmọ-ogun rẹ̀, àti ilẹ̀ rẹ̀. ìwọ ó ṣe i gẹ́gẹ́ ìwọ ti ṣe Sihoni ọba Amori ẹni ó ń jẹ ọba Heṣboni."

3 Bẹ́̀ ni Olúwa Ọlọ́run wa fi Ogu ọba Baṣani àti àwọn jagunjagun rẹ̀ wa lọ́wọ́. A kọlù wọ́n títí fi ku ẹnìkan fún un láàyè. 4 ìgbà náà a gba gbogbo àwọn ìlú rẹ̀. ̀kankan a gbà nínú àwọn ọgọta ìlú wọ́n , gbogbo agbègbè Argobu, lábẹ́ ìjọba Ogu Baṣani. 5 Gbogbo ìlú wọ̀nyí a mọ odi gíga yíká pẹ̀àwọn ìlẹ̀kùn àti irin. ̀pọ̀ àwọn ìlú kéékèèké a mọ odi yíká tún pẹ̀. 6 Gbogbo wọn ni a parun pátápátá gẹ́gẹ́ á ti ṣe Sihoni ọba Heṣboni, a pa gbogbo ìlú wọn run pátápátá: tọkùnrin tobìnrin àti àwọn ọmọ wọn. 7 Ṣùgbọ́n a gbogbo ohun ̀sìn àti ìkógun àwọn ìlú wọn, fún ara wa.

8 ìgbà náà ni a ti gba ilẹ̀ ó Jordani láti odò Arnoni, títí orí òkè Hermoni lọ́wọ́ àwọn ọba Amori méjèèjì wọ̀nyí. 9 (Àwọn ará Sidoni ń pe Hermoni Sirioni. Àwọn Amori ń é Seniri). 10 Gbogbo àwọn ìlú ó orí òkè olórí títẹ́ náà ni a gbà àti gbogbo Gileadi, àti gbogbo Baṣani, títí Saleka, àti Edrei, ìlú àwọn ọba Ogu ilẹ̀ Baṣani. 11 (Ogu í ṣe ọba Baṣani nìkan ni ó ṣẹ́nínú àwọn ará Refaimu. Ibùsùn rẹ̀ ni a fi irin ṣe, ó gùn ju ẹsẹ̀ bàtà mẹ́tàlá lọ gígùn àti ẹsẹ̀ bàtà mẹ́ìbú. Èyí Rabba ti àwọn Ammoni.)

Pínpín ilẹ̀ náà

12 Nínú àwọn ilẹ̀ a gbà ìgbà náà, mo fún àwọn ọmọ Reubeni àti àwọn ọmọ Gadi, ilẹ̀ ó àríwá Aroeri níbi odò Arnoni, pọ̀ mọ́ ìdajì ilẹ̀ òkè Gileadi pẹ̀gbogbo ìlú wọn. 13 Gbogbo ìyókù Gileadi àti gbogbo Baṣani, ilẹ̀ ọba Ogu ni mo fún ìdajì ̀Manase. (Gbogbo agbègbè Argobu ni Baṣani a mọ̀ ilẹ̀ àwọn ará Refaimu. 14 Jairi ̀kan nínú àwọn ìran Manase gba gbogbo agbègbè Argobu títí ààlà àwọn ará Geṣuri àti àwọn ará Maakati; a sọ ibẹ̀ orúkọ rẹ̀ torí èyí ni Baṣani fi ń jẹ́ Hafoti-Jairi títí di òní.) 15 Mo fi Gileadi fún Makiri, 16 ṣùgbọ́n àwọn ọmọ Reubeni àti ọmọ Gadi ni mo fún ilẹ̀ láti Gileadi lọ odò Arnoni (àárín odò náà jẹ́ ààlà) títí ó fi odò Jabbok. Èyí i ṣe ààlà àwọn ará Ammoni. 17 Pẹ̀tẹ́lẹ̀ Arabah pẹ̀, àti Jordani gẹ́gẹ́ òpin ilẹ̀ rẹ̀, láti Kinnereti lọ títí Òkun pẹ̀tẹ́lẹ̀ Arabah, àní Òkun Iyọ̀, ìsàlẹ̀ àwọn orísun Pisga ìhà ìlà-oòrùn.

18 Mo pàṣẹ fún un yín ìgbà náà , "Olúwa Ọlọ́run yín ti fi ilẹ̀ yìí fún un yín láti i. Ṣùgbọ́n, gbogbo àwọn ọkùnrin yín ó lera wọ́n ti dira ogun, gbọdọ̀ kọjá síwájú àwọn arákùnrin yín: ará Israẹli. 19 Àwọn ̀a yín, àwọn ọmọ yín àti àwọn ohun ̀sìn in yín (mo mọ̀ ti ohun ̀sìn púpọ̀) dúró àwọn ìlú mo fi fún un yín, 20 títí di ìgbà Olúwa yóò fún àwọn arákùnrin yín ìsinmi ó ti fún un yín, àti ìgbà àwọn náà yóò fi gba ilẹ̀ náà Olúwa Ọlọ́run yín ti fún wọn ìhà kejì Jordani. Nígbà náà ni ̀kọ̀̀kan yín padà lọ ìní rẹ̀ mo fún un."

A gba Mose láààyè láti kọjá Jordani

21 Nígbà náà ni mo pàṣẹ fún Joṣua , "Ìwọ fi ojú rẹ ohun gbogbo Olúwa Ọlọ́run rẹ ṣe àwọn ọba méjèèjì wọ̀nyí. Bẹ́̀ ni Olúwa yóò ṣe àwọn ilẹ̀ ọba ̀yin n lọ. 22 ṣe bẹ̀wọn, Olúwa Ọlọ́run yín tìkára rẹ̀ ni yóò fún un yín."

23 Nígbà náà ni mo bẹ Olúwa , 24 "Olúwa Olódùmarè, ìwọ bẹ̀rẹ̀ fi títóbi rẹ àti ọwọ́ agbára rẹ han ìránṣẹ́ rẹ. Ọlọ́run wo bẹ́̀ láyé àti lọ́run ó ṣe àwọn iṣẹ́ agbára ńlá o ti ṣe? 25 Jẹ́ n kọjá lọ wo ilẹ̀ rere ti ìkọjá Jordani, ilẹ̀ òkè dídára àti Lebanoni."

26 Ṣùgbọ́n torí i tiyín, Olúwa Ọlọ́run bínú mi gbọ́ tèmi. Olúwa sọ , "Ó gẹ́́, ìwọ gbọdọ̀ sọ ohunkóhun lórí ̀rọ̀ yìí mi mọ́. 27 Gòkè lọ orí òkè Pisga, yíká ìwọ̀-oòrùn, ìlà-oòrùn, àríwá àti gúúsù. Fi ojú ara rẹ wo ilẹ̀ náà níwọ̀n ìwọ kọjá Jordani yìí. 28 Ṣùgbọ́n yan Joṣua, o gbà á níyànjú, un lọ́kàn le, torí òun ni yóò síwájú àwọn ènìyàn wọ̀nyí kọjá, yóò jẹ́ wọn jogún ilẹ̀ náà ìwọ yóò ." 29 Báyìí ni a dúró àfonífojì ̀Beti-Peori.

Veja também

Publicidade
Bíblia Online Bíblia Online

Bíblia Online • Versão: 2026-06-28_14-13-17-