Publicidade

Deuteronômio 7

Lílé àwọn orílẹ̀-èdè jáde

1 Nígbà Olúwa Ọlọ́run rẹ ilẹ̀ náà, ìwọ yóò wọ̀ lọ láti gbà, ìwọ yóò ̀pọ̀lọpọ̀ orílẹ̀-èdè kúrò níwájú rẹ. Àwọn ará Hiti, Girgaṣi, Amori, Kenaani, Peresi, Hifi àti àwọn ará Jebusi. Àwọn orílẹ̀-èdè méje wọ́n lágbára wọ́n pọ̀lọ, 2 nígbà Olúwa Ọlọ́run rẹ ti fi wọ́n lọ́wọ́, ìwọ ti ṣẹ́gun wọn, ìwọ ó pa wọ́n run pátápátá. ṣe wọn ṣe àdéhùn àlàáfíà, ìwọ gbọdọ̀ ṣàánú fún wọn. 3 Ìwọ gbọdọ̀ wọn àna. Àwọn ọmọbìnrin rẹ gbọdọ̀ fẹ́ àwọn ọmọkùnrin wọn, bẹ́̀ ni ìwọ gbọdọ̀ fẹ́ àwọn ọmọbìnrin wọn fún àwọn ọmọkùnrin rẹ, 4 torí wọ́n yóò àwọn ọmọ rẹ padà kúrò lẹ́yìn mi, láti jẹ́ wọn máa sin òrìṣà, ìbínú Olúwa yóò sórí rẹ, yóò run yín kíákíá. 5 Èyí ni ṣe wọn, pẹpẹ wọn lulẹ̀, bi òpó òkúta ibi mímọ́ òrìṣà wọn lulẹ̀, òpó òrìṣà Aṣerah wọn ni lulẹ̀ sun ère òrìṣà wọn iná. 6 Torí ènìyàn mímọ́ ni jẹ́ Olúwa Ọlọ́run yín, Olúwa Ọlọ́run yín ti yàn yín láàrín gbogbo ènìyàn lórí ilẹ̀ ayé, láti jẹ́ ènìyàn rẹ̀: ohun ìní iyebíye rẹ̀.

7 Olúwa torí pọ̀ lọ́pọ̀lọ́pọ̀ ju àwọn ènìyàn yòókù lọ yàn yín, ̀yin à lẹ kéré nínú gbogbo ènìyàn. 8 Ṣùgbọ́n torí Olúwa fẹ́ràn yín, ó pa ìbúra ó ṣe pẹ̀àwọn baba ńlá yín mọ́ ni ó ṣe fi ọwọ́ agbára ńlá un yín jáde ó yín padà nínú oko ẹrú, àti láti ọwọ́ agbára Farao ọba Ejibiti. 9 Nítorí náà mọ̀ dájúdájú Olúwa Ọlọ́run yín, Òun ni Ọlọ́run, Ọlọ́run olóòtítọ́ ni, ń pa májẹ̀ìfẹ́ rẹ̀ mọ́ fún ẹgbẹẹgbẹ̀rún ìran, àwọn ó fẹ́ ó ń pa àṣẹ rẹ̀ mọ́. 10 Ṣùgbọ́n

àwọn ó kórìíra rẹ̀ ni yóò san ̀san fún gbangba nípa pípa wọ́n run;

yóò jáfara láti san ̀san fún àwọn ó kórìíra rẹ̀ gbangba.

11 Nítorí náà kíyèsi láti máa tẹ̀àwọn àṣẹ, ìlànà àti òfin mo fun un yín lónìí.

12 ń kíyèsi àwọn òfin wọ̀nyí ń ṣọ́ra láti ṣe wọ́n, nígbà náà ni Olúwa Ọlọ́run yín yóò pa májẹ̀ìfẹ́ rẹ̀ mọ́ fún un yín, ó ti búra fún àwọn baba ńlá a yín. 13 Yóò fẹ́ràn yín, yóò bùkún un yín yóò pọ̀ i. Yóò bùkún èso inú yín, ̀gbìn ilẹ̀ yín, oúnjẹ yín, wáìnì tuntun àti òróró yín, àwọn màlúù, agbo ẹran yín, àti àwọn àgùntàn, ̀wọ́ ẹran yín, ilẹ̀ ó ti búra fún àwọn baba ńlá yín láti fún un yín. 14 A ó bùkún un yín ju gbogbo ènìyàn lọ, ẹni yóò yàgàn nínú ọkùnrin tàbí obìnrin yín, bẹ́̀ ni ̀kan nínú àwọn ohun ̀sìn in yín yóò láìlọ́mọ. 15 Olúwa yóò pa ́ mọ́ kúrò nínú ààrùn gbogbo, yóò jẹ́ èyíkéyìí ààrùn búburú mọ̀ Ejibiti sára yín, ṣùgbọ́n yóò fi wọ́n ara gbogbo àwọn ó kórìíra yín. 16 Gbogbo àwọn ènìyàn Olúwa Ọlọ́run yín fi yín lọ́wọ́ ni parun pátápátá. ṣe ṣàánú fún wọn, ṣe sin olúwa ọlọ́run wọn torí ìdánwò ni èyí jẹ́ fún un yín.

17 máa láàrín ara yín , "Àwọn orílẹ̀-èdè yìí lágbára lọ. Báwo ni a o ṣe wọn jáde?" 18 Ṣùgbọ́n ṣe bẹ̀wọn, rántí dáradára ohun Olúwa Ọlọ́run yín ṣe Farao àti gbogbo Ejibiti. 19 à fi ojú u yín àwọn àdánwò ńlá, àwọn iṣẹ́ àmì àti iṣẹ́ ìyanu ńlá, ọwọ́ agbára àti nínà ọwọ́ Olúwa Ọlọ́run yín fi un yín jáde. Olúwa Ọlọ́run yín yóò ṣe bákan náà gbogbo àwọn ènìyàn náà ń bẹ̀. 20 Pẹ̀lúpẹ̀, Olúwa Ọlọ́run yín yóò rán oyin sáàrín wọn títí àwọn ó sálà wọ́n pamọ́ fún un yín, yóò fi ṣègbé. 21 gbọ̀n jìnnìjìnnì torí wọn, torí Olúwa Ọlọ́run yín ó láàrín yín, Ọlọ́run alágbára ni, àti Ọlọ́run ó tóbi lọ́pọ̀lọ́pọ̀. 22 Olúwa Ọlọ́run yín yóò gbogbo orílẹ̀-èdè wọ̀n-ọn-nì kúrò níwájú u yín díẹ̀díẹ̀. A nígbà yín láààyè láti wọn dànù lẹ́̀kan ṣoṣo. àwọn ẹranko igbó ba à gbilẹ̀ i láàrín yín. 23 Ṣùgbọ́n Olúwa Ọlọ́run yín yóò fi wọ́n e yín lọ́wọ́, yóò máa wọ́n sínú dàrúdàpọ̀ títí wọn yóò fi run. 24 Yóò fi àwọn ọba wọn e yín lọ́wọ́, ̀yin ó pa orúkọ wọn rẹ́ lábẹ́ ̀run. ẹni yóò dojú ìjà kọ yín títí ó fi pa wọ́n run. 25 iná sun àwọn ère òrìṣà wọn, ṣe ṣe ojúkòkòrò fàdákà tàbí wúrà ó lára wọn. ṣe un fún ara yín, bẹ́̀ kọ́ yóò jẹ́ ìdẹ̀kùn fún un yín, torí ìríra ni Olúwa Ọlọ́run yín. 26 ṣe ohun ìríra ilé yín, ìwọ ba à di ẹni ìparun i rẹ̀. kórìíra rẹ̀ á ìríra pátápátá, torí a á sọ́tọ̀ fún ìparun ni.

Veja também

Publicidade
Bíblia Online Bíblia Online

Bíblia Online • Versão: 2026-06-29_22-07-56-