Pular para o conteúdo
Publicidade

Josué 22

Àwọn ̀ti ìlà-oòrùn padà ilẹ̀ ìní wọn

1 22.1-34: Jo 1.12-18; Nu 32.20-22. Joṣua pe àwọn ̀Reubeni, ̀Gadi àti ìdajì ̀Manase 2 ó sọ fún wọn , "̀yin ti ṣe gbogbo èyí Mose ìránṣẹ́ Olúwa pàṣẹ, ti ṣe ìgbọ́ràn ohun gbogbo mo pàṣẹ. 3 fi àwọn arákùnrin yín sílẹ̀ láti ìgbà títí di òní, ṣùgbọ́n ti kíyèsára láti pa òfin Olúwa Ọlọ́run yín mọ́. 4 Nísinsin yìí Olúwa Ọlọ́run yín ti fún àwọn arákùnrin yín ìsinmi gẹ́gẹ́ ó ti ṣèlérí, padà ilẹ̀ yín níbi Mose ìránṣẹ́ Olúwa fi fún yin òdìkejì Jordani. 5 Ṣùgbọ́n ṣọ́ra gidigidi láti pa àṣẹ àti òfin Mose ìránṣẹ́ Olúwa fi fún yin mọ́. Láti fẹ́ràn Olúwa Ọlọ́run yín, láti rìn nínú gbogbo ̀rẹ̀, láti gbọ́rọ̀ àṣẹ rẹ̀, láti dìímú ṣinṣin àti láti sìn ín pẹ̀gbogbo ọkàn yín àti gbogbo àyà yín."

6 Nígbà náà ni Joṣua súre fún wọn, ó jẹ́ wọn máa lọ ilẹ̀ wọn. 7 (Mose ti fi ilẹ̀ fún ìdajì ̀Manase Baṣani, Joṣua ti fún ìdajì ̀yòókù ilẹ̀ ìwọ̀-oòrùn Jordani, pẹ̀àwọn arákùnrin wọn). Joṣua súre fún wọn ó jẹ́ wọn máa lọ ilẹ̀ wọn, 8 Ó , "padà ilẹ̀ yín pẹ̀ọrọ̀ púpọ̀ yín, pẹ̀agbo ẹran ̀sìn, pẹ̀fàdákà, wúrà, idẹ àti irin, àti ̀pọ̀lọpọ̀ aṣọ, pín ìkógun gbà láti ̀dọ̀ àwọn ̀yín pẹ̀àwọn arákùnrin yín."

9 Báyìí ni àwọn ̀Reubeni, ̀Gadi àti ìdajì ̀Manase fi àwọn ará Israẹli sílẹ̀ Ṣilo Kenaani láti padà Gileadi, ilẹ̀ wọn, èyí wọ́n ti gbà gẹ́gẹ́ àṣẹ Olúwa láti ẹnu Mose .

10 Nígbà wọ́n Geliloti ̀Jordani ilẹ̀ Kenaani, àwọn ̀Reubeni, ̀Gadi àti ìdajì ̀Manase mọ pẹpẹ ńlá ó tóbi kan ̀Jordani. 11 Nígbà àwọn ọmọ Israẹli gbọ́ àwọn ọmọ Reubeni, àti àwọn ọmọ Gadi àti ìlàjì ̀Manase mọ pẹpẹ kan dojúkọ ilẹ̀ Kenaani Geliloti ̀Jordani ìhà kejì àwọn ọmọ Israẹli, 12 gbogbo àjọ Israẹli péjọ Ṣilo láti lọ wọn jagun.

13 Àwọn ọmọ Israẹli rán Finehasi ọmọ Eleasari àlùfáà, ilẹ̀ Gileadi, Reubeni, Gadi àti ìdajì ̀Manase. 14 Pẹ̀rẹ̀ wọ́n rán àwọn ọkùnrin olóyè mẹ́wàá, ẹnìkan fún ̀Israẹli kọ̀̀kan, olórí ̀kọ̀̀kan tiwọn jẹ́ olórí ìdílé láàrín àwọn ọmọ Israẹli.

15 Nígbà wọ́n lọ GileadiReubeni, Gadi àti ìdajì ̀Manasewọ́n sọ fún wọn , 16 "Gbogbo àjọ ènìyàn Olúwa pe, A fẹ́ mọ ìdí fi sẹ̀ Ọlọ́run Israẹli nípa yíyí padà kúrò lọ́dọ̀ rẹ̀ kọ́ pẹpẹ ìṣọ̀tẹ̀ ìlòdì Olúwa? 17 ̀ṣẹ̀ Peori ha fún wa ? Títí di òní yìí àwa ì wẹ ara wa mọ́ kúrò nínú ̀ṣẹ̀ náà, ó tilẹ̀ jẹ́ àjàkálẹ̀-ààrùn ti láàrín ènìyàn Olúwa! 18 Ṣé tún ń padà kúrò lẹ́yìn Olúwa ni báyìí?

" ̀yin ṣọ̀tẹ̀ Olúwa òní, ̀la òun o bínú gbogbo ìpéjọpọ̀ Israẹli. 19 ilẹ̀ ìní yín di àìmọ́, orí ilẹ̀ ìní Olúwa, ibi àgọ́ Olúwa dúró , pín ilẹ̀ náà pẹ̀wa. Ṣùgbọ́n ṣe ṣọ̀tẹ̀ Olúwa tàbí wa nípa mímọ pẹpẹ fún ara yín, lẹ́yìn pẹpẹ Olúwa Ọlọ́run wa. 20 Nígbà Akani ọmọ Sera ṣe àìṣòótọ́ nípa ohun ìyàsọ́tọ̀, ǹjẹ́ ìbínú orí gbogbo àjọ ènìyàn Israẹli nítorí rẹ̀ ? Òun nìkan kọ́ ni ó fún ̀ṣẹ̀ rẹ̀.’ "

21 Nígbà náà ni Reubeni, Gadi àti ̀Manase sọ nínú ìdáhùn wọn fún àwọn olórí Israẹli . 22 Olúwa Ọlọ́run àwọn ọlọ́run! Olúwa Ọlọ́run àwọn ọlọ́run, Òun mọ̀, jẹ́ Israẹli pẹ̀ó mọ̀! èyí ìṣọ̀tẹ̀ tàbí àìgbọ́ràn Olúwa, ṣe gbà wa òní yìí. 23 àwa ti mọ pẹpẹ wa láti padà kúrò ̀dọ̀ Olúwa àti láti ẹbọ sísun àti ẹbọ oúnjẹ jíjẹ, tàbí ẹbọ àlàáfíà orí rẹ, Olúwa fún ara rẹ̀ gba ̀san.

24 "Bẹ́̀ kọ́! Àwa ṣe èyí ìbẹ̀ọjọ́ àwọn ọmọ yín yóò fún wa , ni ̀yin ṣe pẹ̀Olúwa, Ọlọ́run Israẹli? 25 Olúwa ti fi Jordani ṣe ààlà láàrín àwa àti ̀yinàwọn ọmọ Reubeni àti àwọn ọmọ Gadi! ni ìpín nínú Olúwa.Bẹ́̀ ni àwọn ọmọ yín àwọn ọmọ wa dẹ́kun láti máa bẹ̀Olúwa.

26 "Nítorí èyí ni àwa ṣe , jẹ́ àwa múra láti mọ pẹpẹ kan, ṣùgbọ́n í ṣe fún ẹbọ sísun, tàbí fún àwọn ìrúbọ.27 ̀mìíràn, yóò jẹ́ ̀kan láàrín àwa àti ̀yin àti àwọn ìran ń bọ̀, àwa yóò jọ́sìn fún Olúwa ibi mímọ́ rẹ̀ pẹ̀ẹbọ sísun wa, ẹbọ àti ọrẹ àlàáfíà. Nígbà náà ni ̀yìn ̀la, àwọn ọmọ yín sọ fún tiwa , ìpín nínú ti Olúwa.

28 "Àwa , wọ́n tilẹ̀ sọ èyí fún wa, tàbí àwọn ọmọ wa, a ó dáhùn , "wo àpẹẹrẹ pẹpẹ Olúwa, èyí àwọn baba wa mọ, í ṣe fún ẹbọ sísun àti ẹbọ ṣùgbọ́n fún ̀láàrín àwa àti ̀yin." 

29 "Ọlọ́run jẹ́ àwa ó ṣọ̀tẹ̀ Olúwa, àwa yípadà kúrò ̀dọ̀ rẹ òní nípa mímọ pẹpẹ ẹbọ sísun, ọrẹ oúnjẹ jíjẹ àti ẹbọ lẹ́yìn pẹpẹ Olúwa Ọlọ́run wa ó dúró níwájú àgọ́ rẹ̀."

30 Nígbà Finehasi àlùfáà àti àwọn olórí ìjọ ènìyàn, àwọn olórí ìdílé Israẹli gbọ́ ohun Reubeni, Gadi àti Manase ti sọ, ó dùn mọ́ wọn. 31 Finehasi ọmọ Eleasari, àlùfáà fún Reubeni, Gadi àti Manase , "òní ni àwa mọ̀ Olúwa pẹ̀wa, nítorí ̀yin hùwà àìṣòótọ́ Olúwa orí ̀rọ̀ nísinsin yìí, ̀yin ti yọ àwọn ará Israẹli kúrò ọwọ́ Olúwa".

32 Nígbà náà ni Finehasi ọmọ Eleasari àlùfáà àti àwọn olórí padà Kenaani láti ibi ìpàdé wọn pẹ̀àwọn ̀Reubeni àti ̀Gadi Gileadi, wọ́n ìròyìn tọ àwọn ọmọ Israẹli lọ. 33 Inú wọn dùn láti gbọ́ ìròyìn náà, wọ́n yin Ọlọ́run. Wọn sọ̀rọ̀ mọ́ nípa lílọ wọn jagun láti run ilẹ̀ àwọn ̀Reubeni àti ̀Gadi ń gbé.

34 ̀Reubeni àti ̀Gadi fún pẹpẹ náà orúkọ yìí, "̀láàrín wa Olúwa ni Ọlọ́run."

Veja também