Pular para o conteúdo
Publicidade

Juízes 11

1 Jefta ará Gileadi jẹ́ akọni jagunjagun. Gileadi ni baba rẹ̀; ṣùgbọ́n ìyá rẹ̀ jẹ́ panṣágà. 2 Ìyàwó Gileadi àwọn ọmọkùnrin fún un, nígbà àwọn ọmọkùnrin wọ̀nyí dàgbà, wọ́n rán Jefta jáde kúrò nílé, wọ́n , "Ìwọ yóò ogún kankan ìdílé wa, nítorí ìwọ jẹ́ ọmọ obìnrin mìíràn." 3 Jefta kúrò lọ́dọ̀ àwọn arákùnrin rẹ̀, ó pàgọ́ ilẹ̀ Tobu, ó ń gbé níbẹ̀, níbẹ̀ ni àwọn ènìyàn kan ti ń tẹ òfin lójú parapọ̀ láti máa tẹ̀e kiri.

4 àsìkò kan, nígbà àwọn ará Ammoni dìde ogun àwọn Israẹli, 5 Ó ṣe nígbà àwọn Ammoni Israẹli jagun, àwọn àgbàgbà Gileadi tọ Jefta lọ láti é láti ilẹ̀ Tobu. 6 Wọ́n fún Jefta , "o jẹ́ olórí ogun wa a kọjú ogun àwọn ará Ammoni."

7 Jefta fún àwọn àgbàgbà Gileadi , "Ṣé í ṣe kórìíra mi mi kúrò ilé baba mi? fi tọ̀ báyìí nígbà nínú wàhálà?"

8 Àwọn àgbà Gileadi fún Jefta , "Nítorí rẹ̀ ni àwa fi yípadà báyìí: tẹ̀wa, a dojú ìjà kọ àwọn ará Ammoni, ìwọ yóò jẹ olórí wa àti gbogbo àwa ń gbé Gileadi."

9 Jefta fún àwọn àgbàgbà Gileadi , "̀yin mi padà láti àwọn ará Ammoni àti Olúwa fi wọ́n mi lọ́wọ́: ṣe èmi yóò jẹ́ olórí yín nítòótọ́?"

10 Àwọn àgbàgbà Gileadi fún Jefta , "Àwa fi Olúwa ṣe ẹlẹ́rìí: àwa yóò ṣe ohunkóhun o ." 11 Jefta tẹ̀àwọn àgbàgbà Gileadi lọ, àwọn ènìyàn náà fi ṣe olórí àti ̀gágun wọn. Jefta tún sọ gbogbo àwọn ̀rọ̀ ó ti sọtẹ́lẹ̀ níwájú Olúwa Mispa.

12 Jefta rán àwọn oníṣẹ́ ọba àwọn ará Ammoni , "ni ̀sùn o wa láti fi kàn ìwọ fi dojú ìjà kọ ilẹ̀ wa?"

13 Ọba àwọn Ammoni àwọn oníṣẹ́ Jefta lóhùn , "Nígbà àwọn ọmọ Israẹli jáde ti Ejibiti . Wọ́n gba ilẹ̀ mi láti Arnoni Jabbok, àní Jordani, nítorí náà wọn padà lọ àlàáfíà àti pẹ̀lẹ́ kùtù."

14 Jefta tún ránṣẹ́ padà ọba àwọn ará Ammoni 15 ó fún un ,

"Báyìí ni Jefta : àwọn ọmọ Israẹli gba ilẹ̀ Moabu tàbí ilẹ̀ àwọn ará Ammoni. 16 Ṣùgbọ́n nígbà wọ́n jáde kúrò Ejibiti àwọn ọmọ Israẹli la aginjù kọjá lọ ̀Òkun Pupa wọ́n lọ Kadeṣi. 17 Nígbà náà Israẹli rán àwọn oníṣẹ́ ọba Edomu , Gbà fún wa láti gba ilẹ̀ rẹ̀ kọjá,ṣùgbọ́n ọba Edomu fetí wọn. Wọ́n tún ránṣẹ́ ọba Moabu bákan náà òun náà kọ̀. Nítorí náà Israẹli dúró Kadeṣi.

18 "Wọ́n rin aginjù kọjá, wọ́n pẹ́ àwọn ilẹ̀ Edomu àti ti Moabu sílẹ̀, nígbà wọ́n gba apá ìlà-oòrùn Moabu, wọ́n tẹ̀apá kejì Arnoni. Wọn wọ ilẹ̀ Moabu, nítorí ààlà rẹ̀ ni Arnoni .

19 "Nígbà náà ni Israẹli rán àwọn oníṣẹ́ Sihoni ọba àwọn ará Amori, ẹni ń ṣe àkóso Heṣboni, wọ́n fún un , Jẹ́ a la ilẹ̀ rẹ kọjá lọ ibùgbé wa.20 Ṣùgbọ́n Sihoni gba Israẹli gbọ́ (fọkàn tán an) láti jẹ́ ó kọjá. Ó gbogbo àwọn ènìyàn rẹ̀ jọ, ó tẹ̀Jahisa láti Israẹli jagun.

21 "Olúwa Ọlọ́run Israẹli fi Sihoni àti àwọn ọmọ-ogun rẹ̀ Israẹli lọ́wọ́, wọ́n ṣẹ́gun wọn. Israẹli gba gbogbo ilẹ̀ àwọn ará Amori wọ́n ń gbé agbègbè náà, 22 wọ́n gbà gbogbo agbègbè àwọn ará Amori, láti Arnoni ó fi Jabbok, àti láti aginjù Jordani.

23 "Wàyí o, nígbà Olúwa Ọlọ́run Israẹli, ti àwọn ará Amori kúrò níwájú àwọn ènìyàn rẹ̀; Israẹli, ̀tọ́ wo ni láti gba ilẹ̀ náà? 24 Ǹjẹ́ ìwọ yóò ha gba èyí Kemoṣi òrìṣà rẹ fi fún ? Bákan náà àwa yóò gba èyíkéyìí Olúwa Ọlọ́run wa fi fún wa. 25 Ǹjẹ́ ìwọ ha sàn ju Balaki ọmọ Sippori, ọba Moabu lọ? Ǹjẹ́ òun ha ṣe gbólóhùn asọ̀ pẹ̀Israẹli ? Tàbí òun dojú ìjà kọ wọ́n ? 26 Fún ̀́dúnrún (300) ọdún ni Israẹli fi ṣe àtìpó Heṣboni, Aroeri àti àwọn ìgbèríko àti àwọn ìlú ó Arnoni . Èéṣe ìwọ fi gbà wọ́n padà àsìkò náà? 27 Èmi kọ́ ni ó ṣẹ̀ ́, ṣùgbọ́n ìwọ ni ó ṣẹ̀ nípa kíkógun tọ̀ . Jẹ́ Olúwa olùdájọ́, ṣe ìdájọ́ lónìí láàrín àwọn ọmọ Israẹli àti àwọn ará Ammoni."

28 Ṣùgbọ́n ọba àwọn Ammoni fetí iṣẹ́ Jefta rán i.

29 ̀Olúwa Jefta òun la Gileadi àti Manase kọjá. Ó la Mispa àti Gileadi kọjá láti ibẹ̀, ó tẹ̀síwájú láti àwọn ará Ammoni . 30 Jefta jẹ́ ̀jẹ́ fún Olúwa , "ìwọ fi àwọn ará Ammoni mi lọ́wọ́, 31 yóò ṣe, ohunkóhun ó jáde láti ẹnu-ọ̀ilé mi láti pàdé mi, nígbà èmi ń padà bọ̀ láti ̀dọ̀ àwọn ọmọ Ammoni àlàáfíà, yóò jẹ́ ti Olúwa, èmi yóò fi ẹbọ ọrẹ ẹbọ sísun."

32 Jefta jáde lọ láti àwọn ará Ammoni jagun, Olúwa fi wọ́n e lọ́wọ́. 33 Òun ṣẹ́gun wọn, ó pa wọ́n à pa tán láti Aroeri títí agbègbè Minniti, ó jẹ́ ogún ìlú, títí Abeli-Keramimu. Báyìí ni Israẹli ti ṣẹ́gun àwọn ará Ammoni.

34 Nígbà Jefta padà ilé rẹ̀ Mispa, ó, ọmọ rẹ̀ obìnrin ń jáde bọ̀ pàdé rẹ̀ pẹ̀timbrili àti ijó. Òun ni ọmọ kan ṣoṣo ó : ọmọkùnrin àti ọmọbìnrin mìíràn yàtọ̀ òun nìkan. 35 ìgbà ó i ó fa aṣọ rẹ̀ ya ìbànújẹ́, ó , "Háà! ̀dọ́mọbìnrin mi, ìwọ fún mi ìbànújẹ́ ọkàn ìwọ rẹ̀ sílẹ̀ gidigidi, nítorí èmi ti ya ẹnu mi Olúwa ̀jẹ́, èmi le sẹ́ ̀jẹ́ mi."

36 Ọmọ náà dáhùn , "Baba mi ìwọ ti jẹ́ ̀jẹ́ fún Olúwa, ṣe mi gẹ́gẹ́ ìlérí rẹ, báyìí Olúwa ti gba ̀san fún lára àwọn ̀rẹ, àwọn ará Ammoni. 37 Ṣùgbọ́n yọ̀ǹda ìbéèrè kan yìí fún mi, gbà láààyè oṣù méjì láti rìn orí àwọn òkè, n sọkún pẹ̀àwọn ẹlẹgbẹ́ mi torí mo jẹ́ wúńdíá n ṣe ìgbéyàwó."

38 Jefta lóhùn , "Ìwọ lọ." Ó gbà á láààyè láti lọ fún oṣù méjì. Òun àti àwọn ọmọbìnrin yòókù lọ orí àwọn òkè, wọ́n sọkún nítorí yóò ṣe ìgbéyàwó. 39 Lẹ́yìn oṣù méjì náà, ó padà tọ baba rẹ̀ òun ṣe i ̀jẹ́ ó ti jẹ́. Ọmọ náà jẹ́ wúńdíá mọ ọkùnrin .

Èyí bẹ̀rẹ̀ àṣà kan Israẹli 40 ọjọ́ mẹ́rin láàrín ọdún àwọn obìnrin Israẹli a máa lọ láti ṣọ̀fọ̀ àti ṣe ìrántí ọmọbìnrin Jefta ti Gileadi.

Veja também