Publicidade

Juízes 16

Samsoni àti Dẹlila

1 ọjọ́ kan Samsoni lọ Gasa níbi ó ti obìnrin panṣágà kan. Ó wọlé tọ̀ ́ láti sun ̀dọ̀ rẹ̀ òru ọjọ́ náà. 2 Àwọn ará Gasa gbọ́ , "Samsoni níbí." Wọ́n agbègbè náà , wọ́n ń ṣọ́ gbogbo òru náà ẹnu-bodè ìlú náà. Wọn mira gbogbo òru náà "àfẹ̀mọ́júmọ́ àwa yóò pa á."

3 Ṣùgbọ́n Samsoni sùn níbẹ̀ di àárín ̀gànjọ́. Òun dìde ̀gànjọ́, ó fi ọwọ́ di àwọn ìlẹ̀kùn odi ìlú náà , pẹ̀òpó méjèèjì, ó wọ́n tu, pẹ̀ìdábùú àti ohun gbogbo ó lára rẹ̀. Ó gbé wọn èjìká rẹ̀ òun gbé wọn lọ orí òkè ó kọjú Hebroni.

4 Lẹ́yìn ìgbà díẹ̀, ó ìfẹ́ obìnrin kan àfonífojì Soreki, orúkọ ẹni í ṣe Dẹlila. 5 Àwọn ìjòyè Filistini lọ obìnrin náà, wọ́n sọ fún un , "ìwọ le tàn án òun fi àṣírí agbára rẹ̀ hàn ́, àti àwa ó ti borí rẹ̀, àwa é àwa ṣẹ́gun rẹ̀. Ẹnìkọ̀̀kan nínú wa yóò fún ̀́dẹ́gbẹ̀fàdákà."

6 Torí náà Dẹlila sọ fún Samsoni , "Sọ àṣírí agbára ńlá rẹ fún mi àti wọ́n ti le ́, àti wọ́n ṣe borí rẹ."

7 Samsoni a lóhùn , "ẹnikẹ́ni fi okùn tútù méje ẹnìkan gbẹ , èmi yóò di aláìlágbára i gbogbo àwọn ọkùnrin yòókù."

8 Àwọn olóyè Filistini okùn tútù méje ẹnikẹ́ni gbẹ fún Dẹlila òun fi wọ́n é. 9 Nígbà àwọn ènìyàn pamọ́ sínú yàrá, òun , "Samsoni àwọn Filistini ti láti ." Ṣùgbọ́n òun àwọn okùn náà òwú ti í nígbà ó lẹ́bàá iná. Torí náà wọn mọ àṣírí agbára rẹ̀.

10 Dẹlila sọ fún Samsoni , ìwọ ti tàn ; o purọ́ fún mi. báyìí o sọ a ti ṣe le ́.

11 Òun dáhùn , "wọ́n fi okùn tuntun ẹnikẹ́ni ì dáradára, èmi yóò di aláìlágbára, èmi yóò dàbí àwọn ọkùnrin yòókù."

12 Dẹlila àwọn okùn tuntun, ó fi wọ́n í. Nígbà àwọn ọkùnrin Filistini ti fi ara pamọ́ sínú yàrá, òun kígbe i , "Samsoni àwọn Filistini láti ," òun okùn náà kúrò ọwọ́ rẹ̀ òwú.

13 Dẹlila tún sọ fún Samsoni , "Títí di ìsinsin yìí ìwọ ń tún tàn , o tún purọ́ fún mi. Sọ fún mi ̀wọ́n fi le ́."

Samsoni a lóhùn , "ìwọ hun ìdí irun méjèèje ó orí mi pẹ̀okùn, ó le dáradára o fi ̀un mọ́lẹ̀, èmi yóò di aláìlágbára àwọn ọkùnrin yòókù." Nígbà òun ti sùn, Dẹlila hun àwọn ìdí irun méjèèje ó orí rẹ̀, 14 ó fi ìhunṣọ wọ́n.

Ó tún é , "Samsoni àwọn Filistini láti ." Òun ojú oorun, ó fa ìdè ìhunṣọ náà tu pẹ̀ohun gbogbo wọ́n fi kàn án mọ́lẹ̀.

15 Dẹlila sọ fún un , "Èéṣe ìwọ fi , Èmi fẹ́ràn rẹ,nígbà ìwọ fi ọkàn tán mi. Èyí ni ìgbà kẹta ìwọ ti tàn jẹ, ìwọ sọ àṣírí ibi agbára ńlá rẹ gbé fún mi." 16 Ó ṣe nígbà ó fi ̀rọ̀ rẹ̀ rọ̀ ́ ojoojúmọ́ pẹ̀̀rọ̀ rẹ̀ títí bi ó òpin ̀rẹ̀.

17 Òun sọ ohun gbogbo ó ọkàn rẹ̀ fún un. Ó , "Abẹ ì kan orí mi , nítorí Nasiri, ẹni ìyàsọ́tọ̀ fún Ọlọ́run ni mo jẹ́ láti ìgbà ìbí mi . a irun orí mi, agbára mi yóò fi sílẹ̀, èmi yóò di aláìlágbára àwọn ọkùnrin yòókù."

18 Nígbà Dẹlila i ó ti sọ ohun gbogbo fún òun tan, Dẹlila ránṣẹ́ àwọn ìjòyè Filistini , "lẹ́̀kan i, ó ti sọ ohun gbogbo fún mi." Torí náà àwọn olóyè Filistini padà, wọ́n owó ìpinnu náà lọ́wọ́. 19 Òun Samsoni sùn lórí itan rẹ̀, òun pe ọkùnrin kan láti àwọn ìdì irun orí rẹ̀ méjèèje, òun bẹ̀rẹ̀ ṣẹ́gun rẹ̀. Agbára rẹ̀ fi í sílẹ̀ lọ.

20 Òun é , "Samsoni àwọn Filistini láti ."

Òun ojú oorun rẹ̀, ó sọ , "Èmi yóò jáde lọ í ti àtẹ̀yìnwá, èmi gba ara mi, n di òmìnira." Ṣùgbọ́n òun mọ̀ Olúwa ti fi òun sílẹ̀.

21 Nígbà náà ni àwọn Filistini un, wọ́n yọ ojú rẹ̀ méjèèjì wọ́n un lọ Gasa. Wọ́n fi ṣẹ́kẹ́ṣẹkẹ̀ idẹ é, wọ́n fi ibi iṣẹ́ ọlọ lílọ̀ nínú ilé túbú. 22 Ṣùgbọ́n irun orí rẹ̀ bẹ̀rẹ̀ í tún lẹ́yìn ìgbà wọ́n ti a.

Ikú Samsoni

23 Àwọn ìjòyè, àwọn ará Filistini péjọpọ̀ láti ṣe ìrúbọ ńlá Dagoni ọlọ́run wọn àti láti ṣe ayẹyẹ wọ́n , ọlọ́run wa ti fi Samsoni ̀wa wa lọ́wọ́.

24 Nígbà àwọn ènìyàn Samsoni wọ́n yin ọlọ́run wọn ,

"Ọlọ́run wa ti fi ̀wa

wa lọ́wọ́.

Àní ẹni ó ti run ilẹ̀ wa

ẹni ó ti pa ̀pọ̀lọpọ̀ nínú wa."

25 Nígbà inú wọn dùn gidigidi wọ́n ń yọ ayọ̀ ńlá, wọ́n pariwo , Samsoni ó wa lára . Wọ́n pe Samsoni jáde láti ọgbà ̀wọ̀n náà, òun ń ṣeré fún wọn.

Nígbà wọ́n un dúró láàrín àwọn òpó. 26 Samsoni sọ fún àwọn ìránṣẹ́ ó di ọwọ́ rẹ̀ , "fi si ibi ọwọ́ mi yóò ti le àwọn òpó ó gbé tẹmpili dúró , èmi fẹ̀yìn wọ́n." 27 àsìkò náà, tẹmpili yìí kún fún àwọn ọkùnrin àti obìnrin; gbogbo àwọn ìjòyè Filistini níbẹ̀, òkè ilé náà, níbi ẹgbẹ̀rún mẹ́ta (3,000) àwọn ọkùnrin àti obìnrin ń wòran Samsoni òun ti ń ṣeré. 28 Nígbà náà ni Samsoni pe Olúwa , "Olúwa Olódùmarè, rántí mi. Háà Ọlọ́run jọ̀wọ́ fi agbára fún mi lẹ́̀kan yìí i, èmi gbẹ̀san lára àwọn Filistini nítorí àwọn ojú mi méjèèjì." 29 Samsoni na ọwọ́ àwọn òpó méjèèjì ó láàrín gbùngbùn, orí àwọn tẹmpili náà dúró , ó fi ọwọ́ ̀tún ̀kan àti ọwọ́ òsì èkejì, ó fi ara wọ́n, 30 Samsoni , "Jẹ́ èmi pẹ̀àwọn Filistini!" Òun fi agbára ńlá wọ́n, bẹ́̀ ni ilé náà lu àwọn ìjòyè àti gbogbo àwọn ó nínú rẹ̀. Báyìí ni ó pa ̀pọ̀lọpọ̀ nígbà ikú rẹ̀ ju ìgbà ayé rẹ̀ lọ.

31 Nígbà náà ni àwọn arákùnrin rẹ̀ àti gbogbo ìdílé baba rẹ̀ àpapọ̀ gòkè lọ wọ́n gbé e, wọ́n gbé e padà , wọ́n sin ín agbede-méjì Sora àti Eṣtaoli, sínú ibojì Manoa baba rẹ̀. Òun ti ṣe àkóso Israẹli ogún ọdún.

Veja também

Bíblia Online Bíblia Online

Bíblia Online • Versão: 2026-07-05_19-25-13-