Pular para o conteúdo
Publicidade

Juízes 9

Abimeleki

1 ọjọ́ kan Abimeleki ọmọ Jerubbaali lọ ̀dọ̀ àwọn arákùnrin ìyá rẹ̀ Ṣekemu ó wọn sọ̀rọ̀ àti gbogbo àwọn ìbátan ìyá rẹ̀ , 2 "bi gbogbo àwọn ará Ṣekemu léèrè, Èwo sàn fún un yín, ṣé gbogbo àwọn àádọ́rin ọmọ Jerubbaali jẹ ọba lórí yín ni tàbí ẹnìkan ṣoṣo ṣe àkóso yín?Ṣùgbọ́n rántí ẹran-ara yín àti ̀jẹ̀ yín ni èmi ń ṣe."

3 Nígbà àwọn arákùnrin rẹ̀ sọ èyí etí àwọn ará Ṣekemu, ọkàn wọn àti tẹ̀Abimeleki torí, wọ́n sọ , "Arákùnrin wa í ṣe." 4 Wọ́n fún un àádọ́rin ṣékélì fàdákà láti ilé òrìṣà Baali-Beriti, Abimeleki fi owó náà gba àwọn jàǹdùkú àti aláìníláárí ènìyàn wọ́n di olùtẹ̀rẹ̀. 5 Ó wọn lọ ilé baba rẹ̀ Ofira, níbẹ̀ orí òkúta kan ṣoṣo ni ó ti pa àádọ́rin nínú àwọn arákùnrin rẹ̀, àwọn Jerubbaali, ṣùgbọ́n Jotamu, àbíkẹ́yìn nínú àwọn ọmọ Jerubbaali, bọ́ yọ nítorí ó pamọ́. 6 Gbogbo àwọn ará Ṣekemu àti àwọn ará Beti-Milo pàdé pọ̀ ̀igi óákù ibi òpó Ṣekemu láti fi Abimeleki jẹ ọba.

7 Nígbà wọ́n sọ ohun ó ń ṣẹlẹ̀ yìí fún Jotamu, ó gun orí ṣóńṣó òkè Gerisimu lọ, ó lóhùn rara , "tẹ́mi, ̀yin àgbàgbà Ṣekemu, Ọlọ́run le tẹ́yín. 8 ọjọ́ kan àwọn igi jáde lọ láti fi òróró yan ọba fún ara wọn. Wọ́n pe igi Olifi , ṣe ọba wa.

9 "Ṣùgbọ́n igi Olifi wọn lóhùn , Èmi yóò ha fi òróró mi sílẹ̀ èyí a ń láti fi ̀wọ̀ fún àwọn ọlọ́run àti ènìyàn èmi ṣe olórí àwọn igi?

10 "Àwọn igi sọ fún igi ̀pọ̀tọ́ , jẹ ọba orí wa.

11 "Ṣùgbọ́n ̀pọ̀tọ́ wọn lóhùn , èmi fi èso mi ó dára ó dùn sílẹ̀ láti ṣe olórí àwọn igi?

12 "Àwọn igi tún sọ fún àjàrà , , o ṣe ọba wa.

13 "Ṣùgbọ́n àjàrà dáhùn , Ṣé èmi dẹ́kun àti máa so èso wáìnì mi èyí ó ń inú Ọlọ́run àti àwọn ènìyàn dùn láti máa ṣe olórí àwọn igi?

14 "ìparí gbogbo àwọn igi lọ igi ̀gún wọ́n sọ fún un , ó ṣe ọba wa.

15 "Igi ̀gún àwọn igi lóhùn , olóòtítọ́ ni fẹ́ yàn ọba yín. àsálà abẹ́ ibòòji mi; ṣùgbọ́n í ṣe bẹ́̀ jẹ́ iná jáde láti inú igi ̀gún ó àwọn igi kedari àti ti Lebanoni run!

16 "Báyìí ó jẹ́ ̀yin ṣe ohun ó ọlá àti pẹ̀̀òtítọ́ fífi Abimeleki jẹ ọba, ó ṣe ohun ó tọ́ ni ṣe Jerubbaali àti ìdílé rẹ̀, san ̀san yẹ fún un. 17 Nítorí baba mi nítorí yín, ó fi ̀rẹ̀ wéwu láti gbà yín sílẹ̀ lọ́wọ́ àwọn ará Midiani; 18 ṣùgbọ́n lónìí ̀yin ṣọ̀tẹ̀ ilé baba mi, orí òkúta kan ṣoṣo ni ti pa àwọn àádọ́rin ọmọ rẹ̀, ̀yin ti fi Abimeleki ọmọ ẹrúbìnrin rẹ̀ jẹ ọba lórí àwọn ènìyàn Ṣekemu nítorí ó jẹ́ arákùnrin yín. 19 ohun ṣe Jerubbaali àti ìdílé rẹ̀ jẹ́ ohun ó yẹ, ṣe òtítọ́ inú i, ayọ̀ nínú Abimeleki òun náà ayọ̀ nínú yín. 20 Ṣùgbọ́n ṣe bẹ́̀ jẹ́ iná jáde láti ̀dọ̀ Abimeleki ó yín run. ̀yin ará Ṣekemu àti ará Beti-Milo, iná pẹ̀jáde láti ̀dọ̀ yín ̀yin ará Ṣekemu àti ará Beti-Milo ó Abimeleki run."

21 Lẹ́yìn Jotamu ti sọ èyí tan, ó àsálà lọ Beeri, ó gbé níbẹ̀ nítorí ó bẹ̀arákùnrin rẹ̀ Abimeleki.

22 Lẹ́yìn Abimeleki ti ṣe àkóso Israẹli fún ọdún mẹ́ta, 23 Ọlọ́run rán ̀búburú sáàárín Abimeleki àti àwọn ará Ṣekemu, àwọn ẹni ó hu ìwà ̀tẹ̀. 24 Ọlọ́run ṣe èyí láti gbẹ̀san àwọn ìwà búburú, àti ìtàjẹ̀ sílẹ̀ àwọn àádọ́rin ọmọ Jerubbaali lára Abimeleki arákùnrin wọn àti lára àwọn ènìyàn Ṣekemu, ẹni ó ràn án lọ́wọ́ láti pa àwọn arákùnrin rẹ̀. 25 Nítorí ìkórìíra wọ́n ni àwọn olórí, ni Ṣekemu dẹ àwọn ènìyàn àwọn orí òkè láti máa àwọn ènìyàn ń kọjá lọ́, wọn máa wọ́n lólè, àwọn kan sọ èyí fún Abimeleki.

26 Gaali ọmọ Ebedi àti àwọn arákùnrin rẹ̀ Ṣekemu, àwọn ará Ṣekemu gbẹ́kẹ̀wọn, wọ́n fi inú tán wọn. 27 Lẹ́yìn ìgbà wọ́n jáde lọ oko, wọ́n ṣa èso àjàrà wọn jọ, wọ́n fún èso àjàrà náà, wọ́n ṣe àjọ̀dún nínú ilé òrìṣà wọn. Nígbà wọ́n ń jẹ wọ́n ń mu wọ́n fi Abimeleki . 28 Gaali ọmọ Ebedi dáhùn , "Ta ni Abimeleki tàbí ta ni Ṣekemu àwa ó fi sìn ín? Ọmọ Jerubbaali kọ́ ṣe tàbí Sebulu kọ́ igbákejì rẹ̀? sin àwọn ará Hamori baba àwọn ará Ṣekemu, èéṣe a ó fi sin Abimeleki? 29 Ìbá se àwọn ènìyàn yìí abẹ́ ìṣàkóso mi ni! Èmi ìbá bọ́ àjàgà rẹ̀ kúrò ọrùn yín. Èmi yóò fún Abimeleki , gbogbo àwọn ogun rẹ jáde láti .’ "

30 Nígbà Sebulu, alákòóso ìlú náà gbọ́ ohun Gaali ọmọ Ebedi sọ, inú i gidigidi. 31 Ó ránṣẹ́ Abimeleki , "Gaali ọmọ Ebedi àti àwọn arákùnrin rẹ̀ láti máa gbé Ṣekemu ṣùgbọ́n, wọ́n ń àwọn ènìyàn sókè láti ṣọ̀tẹ̀ . 32 òru ìwọ àti àwọn ogun rẹ pamọ́ wọ́n nínú igbó. 33 òwúrọ̀ kùtùkùtù oòrùn ti ń yọ ìwọ yóò wọ inú ìlú náà lọ láti a . Yóò ṣe nígbà Gaali àti àwọn ogun rẹ̀ ó pẹ̀rẹ̀ jáde láti , ìwọ yóò ṣe ohunkóhun o fẹ́ wọn."

34 Abimeleki àti gbogbo àwọn ogun rẹ̀ jáde òru, wọ́n pamọ́ ̀mẹ́rin Ṣekemu . 35 Gaali ọmọ Ebedi jáde síta, ó dúró ẹnu-ọ̀ibodè ìlú náà àkókò Abimeleki àti àwọn ọmọ-ogun rẹ̀ jáde kúrò níbi wọn pamọ́ .

36 Nígbà Gaali àwọn ènìyàn náà, ó sọ fún Sebulu , "ó, àwọn ènìyàn ń ti orí òkè sọ̀kalẹ̀ !"

Sebulu fún un , "Òjìji òkè wọ̀n-ọn-nì ni ìwọ bi ẹni ènìyàn."

37 Gaali ó , "Wòkè, àwọn ènìyàn ń tọ̀ bọ̀ láti agbede-méjì ilẹ̀ àti ̀gbẹ́ kan ń ti ̀igi óákù Meonenimu ."

38 Nígbà náà ni Sebulu a lóhùn , "Níbo ni ẹnu ó ń ṣe ni báyìí. Ṣe o , Ta ni Abimeleki àwa ó fi máa sìn ín?Àwọn ẹni ó gàn án kọ́ nìyí? Jáde lọ o wọn !"

39 Gaali síwájú àwọn ogun ará Ṣekemu lọ kọjú Abimeleki láti wọn jagun. 40 Abimeleki e, ̀pọ̀lọpọ̀ àwọn ọmọ-ogun ṣubú wọ́n gbọgbẹ́ wọ́n ṣe ń sálọ, títí ẹnu-ọ̀ibùdó ìlú náà. 41 Abimeleki dúró Aruma, nígbà Sebulu Gaali àti àwọn arákùnrin rẹ̀ kúrò ni Ṣekemu, jẹ́ wọ́n gbé Ṣekemu mọ́.

42 ọjọ́ kejì àwọn ará Ṣekemu lọ́ oko, ẹnìkan ṣe òfófó rẹ̀ fún Abimeleki. 43 Ó àwọn ènìyàn rẹ̀, ó pín wọn ẹgbẹ́ mẹ́ta ó pamọ́ inú oko. Nígbà ó àwọn ènìyàn náà ń jáde kúrò nínú ìlú, ó dìde ó gbóguntì wọ́n. 44 Abimeleki àti àwọn ọmọ-ogun ó pẹ̀rẹ̀ sáré síwájú, wọ́n gba ẹnu ibodè ìlú náà, wọ́n dúró níbẹ̀. Àwọn ẹgbẹ́ méjì tókù sáré àwọn oko wọ́n gbóguntì wọ́n. 45 gbogbo ọjọ́ náà ni Abimeleki fi àwọn ará ìlú náà , ó ṣẹ́gun wọn, ó pa àwọn ènìyàn ìlú náà ó ìlú náà palẹ̀ pátápátá ó fọ́n iyọ̀ i.

46 Àwọn ènìyàn ilé ìṣọ́ Ṣekemu gbọ́ ohun ó ṣẹlẹ̀, wọ́n sálọ fún ààbò inú ilé ìṣọ́ òrìṣà El-Beriti. 47 Nígbà wọ́n sọ fún Abimeleki gbogbo àwọn ènìyàn ilé ìṣọ́ Ṣekemu ara wọn jọ pọ̀. 48 Abimeleki àti gbogbo àwọn ọmọ-ogun rẹ̀ gun òkè Salmoni lọ. Ó àwọn ̀ka díẹ̀ pẹ̀àáké, ó gbé àwọn ̀ka wọ̀nyí èjìká rẹ̀. Ó sọ fún àwọn ọmọ-ogun rẹ̀ , "ṣe ohun mo ń ṣe yìí kíákíá." 49 Báyìí gbogbo àwọn ọkùnrin ó lọ́dọ̀ rẹ̀ àwọn ̀ka igi wọn tẹ̀Abimeleki. Wọ́n wọn ti ilé ìṣọ́ agbára níbi àwọn ènìyàn pamọ́ wọ́n fi iná i, tóbẹ́̀ gbogbo àwọn ọkùnrin ilé ìṣọ́ Ṣekemu fi pẹ̀. Gbogbo àwọn ènìyàn náà ó ẹgbẹ̀rún (1,000) ènìyàn lọ́kùnrin àti lóbìnrin .

50 Abimeleki tún lọ Tebesi, ó ìlú náà pẹ̀àwọn ọmọ-ogun, ó ṣẹ́gun rẹ̀. 51 Ilé ìṣọ́ kan ó agbára nínú ìlú náà. Gbogbo àwọn ènìyàn ìlú náà ọkùnrin àti obìnrin sínú ilé ìṣọ́ náà. Wọ́n ti ara wọn mọ́ ibẹ̀ wọ́n sálọ inú àjà ilé ìṣọ́ náà. 52 Abimeleki lọ ìsàlẹ̀ ilé ìṣọ́ náà, ó ń a . Ṣùgbọ́n ó ti súnmọ́ ẹnu-ọ̀ilé ìṣọ́ náà láti dáná sun ún, 53 obìnrin kan sọ ọmọ ọlọ lu Abimeleki lórí, ó fọ́ agbárí.

54 ojú kan náà ni ó pe ẹni ó ru àpáta rẹ̀ , "Yára yọ idà rẹ o pa , wọn ba à sọ , Obìnrin ni ó pa á.’ " ̀dọ́mọkùnrin náà fi ̀kọ̀ gún un, ó . 55 Nígbà àwọn ará Israẹli i Abimeleki , olúkúlùkù wọn padà ilé rẹ̀.

56 Báyìí ni Ọlọ́run san ̀san ìwà búburú ti Abimeleki baba rẹ̀ ti pípa ó pa, àwọn àádọ́rin arákùnrin rẹ̀. 57 Ọlọ́run jẹ́ ìwà búburú àwọn ará Ṣekemu pẹ̀padà orí wọn. Ègún Jotamu ọmọ Jerubbaali pàápàá orí wọn.

Veja também