Pular para o conteúdo
Publicidade

Neemias 1

Àdúrà Nehemiah

1 ̀rọ̀ Nehemiah ọmọ Hakaliah.

oṣù Kisleu ogún ọdún (ìjọba Ahaswerusi ọba Persia) nígbà mo ààfin Susa, 2 Hanani, ̀kan nínú àwọn arákùnrin mi láti Juda pẹ̀àwọn ọkùnrin kan, mo béèrè lọ́wọ́ wọn nípa àwọn Júù ó ṣẹ́wọn ìgbèkùn, àti nípa Jerusalẹmu.

3 Wọ́n sọ fún mi , "Àwọn ó a ìgbèkùn wọ́n padà agbègbè ìjọba nínú wàhálà púpọ̀ àti ̀gàn. Odi Jerusalẹmu ti lulẹ̀ a ti fi iná sun ẹnu ibodè rẹ̀."

4 Nígbà mo gbọ́ àwọn nǹkan wọ̀nyí, mo jókòó mo sọkún. Mo ṣọ̀fọ̀, mo gbààwẹ̀, mo gbàdúrà fún ọjọ́ díẹ̀ níwájú Ọlọ́run ̀run. 5 Nígbà náà ni mo :

"Olúwa, Ọlọ́run ̀run, Ọlọ́run ó tóbi ó ̀, ó ń pa májẹ̀ìfẹ́ rẹ̀ mọ́ pẹ̀wọn ó fẹ́ wọ́n ń pa àṣẹ mọ́. 6 Jẹ́ etí rẹ ó ṣí sílẹ̀, ojú ù rẹ ó ṣí sílẹ̀ láti gbọ́ àdúrà ìránṣẹ́ rẹ ń gbà iwájú rẹ ̀sán àti òru fún àwọn ìránṣẹ́ rẹ, àwọn ènìyàn Israẹli. Mo jẹ́wọ́ ̀ṣẹ̀ àwa ọmọ Israẹli àti tèmi àti ti ilé baba mi, a ti ṣẹ̀ . 7 Àwa ti ṣe búburú . A pa àṣẹ ìlànà àti òfin ìwọ fún Mose ìránṣẹ́ rẹ mọ́.

8 "Rántí ìlànà o fún Mose ìránṣẹ́ rẹ, , ìwọ jẹ́ aláìṣòótọ́, èmi yóò fọ́n yín àárín àwọn orílẹ̀-èdè. 9 Ṣùgbọ́n ̀yin yípadà mi, pa àṣẹ mi mọ́, nígbà náà àwọn ènìyàn yín a ìgbèkùn tilẹ̀ jìnnà réré ìpẹ̀kun ̀run, èmi yóò wọn jọ láti ibẹ̀, èmi yóò wọn , ibi èmi ti yàn i ibùgbé fún orúkọ mi.

10 "Àwọn ni ìránṣẹ́ rẹ àti ènìyàn rẹ àwọn ìwọ padà pẹ̀agbára ńlá rẹ àti ọwọ́ agbára ńlá rẹ. 11 Olúwa, jẹ́ etí rẹ ṣí sílẹ̀ àdúrà ìránṣẹ́ rẹ yìí, àti àdúrà àwọn ìránṣẹ́ rẹ wọ́n inú dídùn láti bọ̀wọ̀ fún orúkọ rẹ. Fún ìránṣẹ́ rẹ àṣeyọrí lónìí o síjú àánú ó níwájú ọkùnrin yìí."

Nítorí mo jẹ́ agbọ́ọba nígbà náà.

Veja também