Pular para o conteúdo
Publicidade

Neemias 9

Àwọn ọkùnrin Israẹli jẹ́wọ́ ̀ṣẹ̀ wọn

1 ọjọ́ kẹrìnlélógún oṣù kan náà, àwọn ọmọ Israẹli péjọpọ̀, wọ́n gbààwẹ̀, wọ́n wọ aṣọ ̀fọ̀, wọ́n da eruku sórí ara wọn. 2 Àwọn ọkùnrin Israẹli ya ara wọn sọ́tọ̀ kúrò nínú gbogbo àwọn àjèjì. Wọ́n dúró ààyè e wọn, wọ́n ń jẹ́wọ́ àwọn ̀ṣẹ̀ wọn àti iṣẹ́ búburú àwọn baba wọn. 3 Wọ́n dúró ibi wọ́n , wọ́n fi ìdámẹ́rin ọjọ́ nínú ìwé òfin Olúwa Ọlọ́run wọn, wọ́n tún fi ìdámẹ́rin mìíràn ìjẹ́wọ́ ̀ṣẹ̀ àti sin Olúwa Ọlọ́run wọn. 4 Nígbà náà ni Jeṣua, àti Bani, Kadmieli, Ṣebaniah, Bunni, Ṣerebiah, Bani àti Kenaani gòkè dúró lórí àwọn àtẹ̀gùn àwọn ọmọ Lefi, wọ́n fi ohùn rara kígbe Olúwa Ọlọ́run wọn. 5 Nígbà náà ni àwọn ọmọ Lefi: Jeṣua, Kadmieli, Bani, Haṣbneiah, Ṣerebiah, Hodiah, Ṣebaniah àti Petahiah, "dìde fi ìyìn fún Olúwa Ọlọ́run yín, ó láé àti láéláé."

"Ìbùkún ni fún orúkọ rẹ ó ògo, ó di gbígbéga ju gbogbo ìbùkún àti ìyìn lọ. 6 Ìwọ nìkan ni Olúwa. Ìwọ ni ó ̀run, àní àwọn ̀run ó ga pẹ̀gbogbo ogun wọn, ayé àti ohun gbogbo ń bẹ nínú rẹ̀, òkun, àti ohun gbogbo ń bẹ nínú rẹ̀. Ìwọ pa gbogbo wọn mọ́ láàyè, ogun ̀run ń sìn ́.

7 "Ìwọ ni Olúwa Ọlọ́run, ó yan Abramu ó u jáde láti Uri ti Kaldea, ó sọ orúkọ rẹ̀ Abrahamu. 8 Ìwọ í ọkàn rẹ̀ jẹ́ olóòtítọ́ , ìwọ májẹ̀pẹ̀u rẹ̀ láti fi ilẹ̀ àwọn ará a Kenaani, Hiti, Amori, Peresi, Jebusi àti Girgaṣi fún irú àwọn ọmọ rẹ̀. Ìwọ ti pa ìpinnu rẹ̀ mọ́ nítorí ìwọ jẹ́ olódodo.

9 "Ìwọ ìpọ́njú àwọn baba ńlá wa Ejibiti; ìwọ gbọ́ igbe ẹkún wọn Òkun Pupa. 10 Ìwọ rán iṣẹ́ àmì àti iṣẹ́ ìyanu Farao, gbogbo àwọn ìjòyè rẹ̀ àti gbogbo ènìyàn ilẹ̀ rẹ̀, nítorí ìwọ mọ ìwà ìgbéraga àwọn ará Ejibiti wọn. Ìwọ ra orúkọ fún ara à rẹ, èyí ó títí di òní yìí. 11 Ìwọ pín òkun níwájú wọn, nítorí wọn kọjá ìyàngbẹ ilẹ̀, ṣùgbọ́n ìwọ sọ àwọn ń lépa wọn sínú ibú, òkúta sínú omi ńlá. 12 ̀sán ìwọ darí i wọn pẹ̀̀wọn àwọsánmọ̀ àti òru ni ìwọ darí i wọn pẹ̀̀wọn iná láti fún wọn ìmọ́lẹ̀ ̀wọn yóò gbà.

13 "Ìwọ sọ̀kalẹ̀ orí òkè Sinai; ìwọ wọn sọ̀rọ̀ láti ̀run. Ìwọ fún wọn ìlànà àti àwọn òfin ó jẹ́ òdodo ó tọ́ àti ìlànà ó dára. 14 Ìwọ ọjọ́ ìsinmi rẹ mímọ́ di mọ̀ fún wọn, o fún wọn àwọn ìlànà, àwọn àṣẹ àti àwọn òfin láti ọwọ́ Mose ìránṣẹ́ rẹ. 15 Ìwọ fún wọn oúnjẹ láti ̀run nígbà ebi ń pa wọ́n àti nígbà òǹgbẹ, o fún wọn omi láti inú àpáta; o sọ fún wọn , wọ́n lọ láti lọ gba ilẹ̀ náà ìwọ ti jẹ́ ̀jẹ́ láti fi fún wọn nípa ìgbọ́wọ́sókè.

16 "Ṣùgbọ́n àwọn, baba ńlá wa, wọ́n ṣe ìgbéraga, wọ́n ṣe agídí, wọn tẹríba fún àwọn ìlànà rẹ. 17 Wọ́n kọ̀ láti fetísílẹ̀, wọ́n kùnà láti rántí iṣẹ́ ìyanu ìwọ ṣe àárín wọn. Wọ́n ṣe agídí, nínú ìṣọ̀tẹ̀ wọn, wọ́n yan olórí láti padà oko ẹrú wọn. Ṣùgbọ́n ìwọ Ọlọ́run ó ń dáríjì, olóore-ọ̀fẹ́ àti aláàánú, ó lọ́ra láti bínú, ó pọ̀ ìfẹ́. Nítorí náà ìwọ kọ̀ wọ́n sílẹ̀, 18 nítòótọ́ nígbà wọ́n ṣe ẹgbọrọ màlúù dídá, wọ́n , Èyí ni Ọlọ́run rẹ ó gòkè láti Ejibiti ; tàbí nígbà wọ́n sọ ̀rọ̀-òdì ó burú jàì.

19 "Nítorí àánú ńlá rẹ, ìwọ kọ̀ wọ́n sílẹ̀ aginjù. ̀sán ̀wọn ìkùùkuu kúrò ̀dọ̀ wọn láti ṣe amọ̀an wọn, tàbí ̀wọ́n iná láti tàn wọn òru ̀wọn yóò rìn. 20 Ìwọ fi ̀rere rẹ fún wọn láti kọ́ wọn. Ìwọ manna rẹ dúró ẹnu wọn, ó fún wọn omi fún òǹgbẹ. 21 Fún ogójì ọdún ni ìwọ fi bọ́ wọn aginjù; wọn ṣe aláìní ohunkóhun, aṣọ wọn gbó bẹ́̀ ni ẹsẹ̀ wọn .

22 "Ìwọ fi àwọn ìjọba àti àwọn orílẹ̀-èdè fún wọn, ó fi gbogbo ilẹ̀ náà fún wọ́n. Wọ́n gba ilẹ̀ ọba Sihoni ará a Heṣboni àti ilẹ̀ Ogu ọba Baṣani. 23 Ìwọ ti àwọn ọmọ wọn pọ̀ ìràwọ̀ ojú ̀run, ó wọn ilẹ̀ o ti sọ fún àwọn baba wọn wọn wọ̀, wọn jogún un rẹ̀. 24 Àwọn ọkùnrin wọn wọ inú rẹ̀, wọ́n gbà ilẹ̀ náà. Ìwọ tẹ orí àwọn ará a Kenaani, ń gbé inú ilẹ̀ náà ba níwájú wọn; ó fi àwọn ará a Kenaani wọn lọ́wọ́ pẹ̀àwọn ọba wọn àti àwọn ènìyàn ilẹ̀ náà wọn ṣe wọn ó ti wọ́n. 25 Wọ́n gba àwọn ìlú olódi àti ilẹ̀ ọlọ́ràá; wọ́n gba àwọn ilé ó kún fún onírúurú gbogbo nǹkan rere, àwọn kànga a ti gbẹ́, àwọn ọgbà àjàrà, àwọn ọgbà olifi àti àwọn igi eléso ̀pọ̀lọpọ̀. Wọ́n jẹ, wọ́n , wọ́n sanra dáradára; wọ́n yọ̀ nínú oore ńlá rẹ.

26 "Ṣùgbọ́n wọ́n ṣe àìgbọ́ràn, wọ́n ṣọ̀tẹ̀ ; wọ́n gbàgbé òfin rẹ. Wọ́n pa àwọn wòlíì rẹ, o fi gbà wọn ni ìyànjú wọn padà ; wọ́n se ̀rọ̀-òdì ó burú jàì. 27 Nítorí náà, ìwọ fi wọ́n àwọn ̀wọn lọ́wọ́, àwọn ó ni wọ́n lára. Ṣùgbọ́n nígbà a ni wọ́n lára wọ́n kígbe . Ìwọ gbọ́ wọn láti ̀run àti nínú ̀pọ̀lọpọ̀ àánú rẹ, ìwọ fún wọn olùgbàlà, ó gbà wọ́n lọ́wọ́ àwọn ̀wọn.

28 "Ṣùgbọ́n wọ́n ti nínú ìsinmi, wọn a túnṣe búburú lójú rẹ. Nígbà náà ni ìwọ kọ̀ wọ́n sílẹ̀ ṣọ́wọ́ àwọn ̀wọ́n jẹ ọba lórí wọn. Nígbà wọ́n tún kígbe , ìwọ a gbọ́ láti ̀run , àti nínú àánú rẹ ni ìwọ gbà láti ìgbà ìgbà.

29 "Ìwọ kìlọ̀ fún wọn láti padà sínú òfin rẹ, ṣùgbọ́n wọ́n hu ìwà ìgbéraga, wọ́n ṣe àìgbọ́ràn si àṣẹ rẹ. Wọ́n ṣẹ̀ ìlànà rẹ, nípa èyí ènìyàn yóò wọ́n pa wọ́n mọ́. Nínú agídí ọkàn wọ́n kọ ̀yìn , wọ́n jẹ́ olórí kunkun wọn fẹ́ gbọ́. 30 Fún ̀pọ̀lọpọ̀ ọdún ni ìwọ fi sùúrù pẹ̀wọn. Nípa ̀rẹ ni ìwọ kìlọ̀ fún wọn nípasẹ̀ àwọn wòlíì. Síbẹ̀ wọn fi etí sílẹ̀, nítorí náà ni ìwọ ṣe fi wọ́n àwọn aládùúgbò wọn lọ́wọ́. 31 Ṣùgbọ́n nínú ̀pọ̀ àánú rẹ, ìwọ òpin wọn tàbí kọ̀ wọ́n sílẹ̀, nítorí ìwọ ni Ọlọ́run olóore-ọ̀fẹ́ àti aláàánú.

32 "Ǹjẹ́ nítorí náà, Ọlọ́run wa, Ọlọ́run ó tóbi, ó lágbára, ó ̀, ẹni ó pa májẹ̀ìfẹ́ mọ́, ṣe jẹ́ gbogbo ìnira yìí dàbí ohun kékeré ojú rẹìnira ó ti sórí wa, sórí àwọn ọba wa àti àwọn olórí wa, sórí àwọn àlùfáà wa àti àwọn wòlíì, sórí àwọn baba wa àti sórí gbogbo ènìyàn rẹ̀, láti àwọn ọjọ́ àwọn ọba Asiria títí di òní. 33 Ìwọ jẹ́ olódodo nínú ohun gbogbo ó ti ṣẹlẹ̀ wa; ìwọ ti ṣe òtítọ́, nígbà a ṣe búburú. 34 Àwọn ọba wa, àwọn olórí wa, àwọn àlùfáà wa, àti àwọn baba wa tẹ̀òfin rẹ; wọn fetísílẹ̀ àṣẹ rẹ tàbí àwọn ìkìlọ̀ ìwọ fún wọn. 35 Àní nígbà wọ́n nínú ìjọba wọn, wọ́n ń gbádùn oore ńlá ìwọ fi fún wọn, ilẹ̀ ó tóbi ó lọ́ràá, wọn sìn ́ tàbí padà kúrò nínú àwọn ̀búburú wọn.

36 "Ṣùgbọ́n ó, àwa jẹ́ ẹrú lónìí, àwa jẹ́ ẹrú ilẹ̀ ìwọ fún àwọn baba ńlá wa, nítorí wọn máa jẹ èso rẹ̀ àti ìre mìíràn ó jáde. 37 Nítorí àwọn ̀ṣẹ̀ wa, ̀pọ̀lọpọ̀ ìkórè rẹ lọ ̀dọ̀ àwọn ọba ó fi ṣe olórí wa. Wọ́n ń ṣe àkóso lórí wa àti lórí ẹran wa ó ti wọ́n, àwa nínú ìpọ́njú ńlá.

Àdéhùn àwọn ènìyàn

38 "Nítorí gbogbo èyí, a ń ṣe àdéhùn ó fẹsẹ̀múlẹ̀, a kọ ́ sínú ìwé, àwọn olórí ọmọ Lefi àwọn àlùfáà fi èdìdì í."

Veja também