Publicidade

Casa de Deus

Por Bíblia Online

A casa de Deus é lugar de adoração, refúgio e encontro com o Sagrado. A Bíblia exalta o tabernáculo, o templo e a igreja como morada do Altíssimo entre seu povo.

A presença de Deus

Quão amáveis são os teus tabernáculos! Uma coisa pedi ao Senhor: habitar na casa do Senhor todos os dias da minha vida.

Dídára ọjọ́ kan ààfin rẹ

ju ẹgbẹ̀rún (1,000) ọjọ́ lọ;

èmi o kúkú máa ṣe aṣọ́nínú ilé Ọlọ́run mi

láti gbé àgọ́ àwọn ènìyàn búburú.

Ohun kan ni mo béèrè lọ́dọ̀ Olúwa,

òhun ni èmi yóò máa kiri:

èmi ó le ilé Olúwa

ọjọ́ ayé mi gbogbo,

èmi: ó le kíyèsi ẹwà Olúwa,

èmi ó máa tẹmpili rẹ̀.

Ìbùkún ni fún àwọn o yàn

o wa láti máa gbé àgọ́ rẹ!

A tẹ́ lọ́rùn pẹ̀ohun rere inú ilé rẹ,

ti tẹmpili mímọ́ rẹ.

Orin fún ìgòkè. Ti Dafidi.

Inú mi dùn nígbà wọ́n fún mi ,

"jẹ́ á lọ sílé Olúwa."

Nítòótọ́, ìre àti àánú ni yóò máa tọ̀ lẹ́yìn

ọjọ́ ayé è mi gbogbo,

èmi yóò máa gbé inú ilé Olúwa

títí láéláé.

Ṣùgbọ́n èmi dàbí igi Olifi

ó gbilẹ̀ nínú ilé Ọlọ́run;

èmi gbẹ́kẹ̀ìfẹ́ Ọlọ́run í kùnà

láé àti láéláé.

nítorí ìtara ilé rẹ jẹ run,

àti ̀gàn àwọn ń gàn ́ ṣubú .

O templo

Minha casa será chamada casa de oração. O zelo da tua casa me consumiu. O verdadeiro templo é o corpo do cristão.

Jesu palẹ̀ Tẹmpili mọ́

Jesu wọ inú tẹmpili, Ó àwọn ti ń àti àwọn ń níbẹ̀ jáde. Ó tábìlì àwọn onípàṣípàrọ̀ owó dànù, àti tábìlì àwọn ó ń ta ẹyẹlé. Ó fún wọn , "A à ti kọ ́ , Ilé àdúrà ni a ó máa pe ilé mi,ṣùgbọ́n ̀yin ti sọ ́ di ibùdó àwọn ọlọ́ṣà."

Àjọ ìrékọjá àwọn Júù súnmọ́ etílé, Jesu gòkè lọ Jerusalẹmu, Ó àwọn n ta màlúù, àti àgùntàn, àti àdàbà, àti àwọn onípàṣípàrọ̀ owó nínú tẹmpili wọ́n jókòó: Ó fi okùn tẹ́́rẹ́ ṣe pàṣán, ó gbogbo wọn jáde kúrò nínú tẹmpili, àti àgùntàn àti màlúù; ó da owó àwọn onípàṣípàrọ̀ owó , ó si ti tábìlì wọn ṣubú. Ó fún àwọn ń ta àdàbà , "gbé nǹkan wọ̀nyí kúrò níhìn-ín; ṣe sọ ilé Baba mi di ilé ọjà títà." Àwọn ọmọ-ẹ̀yìn rẹ̀ rántí , a ti kọ ́ , "Ìtara ilé rẹ jẹ run."

Tàbí, ̀yin mọ̀ ara yín ni tẹmpili ̀Mímọ́, ti ń bẹ nínú yín, ti ̀yin ti gbà lọ́wọ́ Ọlọ́run? ̀yin í ṣe ti ara yín,

Ṣùgbọ́n mo pẹ́, ìwọ mọ̀ ó ti yẹ fún àwọn ènìyàn láti máa hùwà nínú ilé Ọlọ́run, í ṣe ìjọ Ọlọ́run alààyè, ̀wọ́n àti ìpìlẹ̀ òtítọ́.

Ṣùgbọ́n Kristi jẹ́ olóòtítọ́ gẹ́gẹ́ ọmọ lórí ilé Ọlọ́run; ilé ẹni àwa jẹ́, àwa gbẹ́kẹ̀e, a di ìṣògo ìrètí wa mu ṣinṣin títí òpin.

"Àwọn baba wa àgọ́ ̀pẹ̀wọn ijù. Èyí a ṣe gẹ́gẹ́ Ọlọ́run ó ba Mose sọ̀rọ̀ ó ṣe é, gẹ́gẹ́ àpẹẹrẹ ó ti . Ti àwọn baba wa ó tẹ̀wọn Joṣua ilẹ̀ ìní àwọn aláìkọlà, Ọlọ́run jáde kúrò níwájú àwọn baba wa, títí àkókò Dafidi. Ẹni ó ojúrere níwájú Ọlọ́run, ó tọrọ láti ibùgbé fún Ọlọ́run Jakọbu. Ṣùgbọ́n Solomoni ni ó kọ́ ilé fún un.

"Ṣùgbọ́n ̀gá-ògo í gbé ilé ti a fi ọwọ́ kọ́, gẹ́gẹ́ wòlíì ti :

" ̀run ni ìtẹ́ mi,

ayé ni àpótí ìtìsẹ̀ mi.

Irú ilé kín ̀yin yóò kọ́ fún mi?

ni Olúwa .

Tàbí níbo ni yóò jẹ́ ibi ìsinmi mi?

Ọwọ́ mi ha ṣe gbogbo nǹkan wọ̀nyí.

Ìdájọ́ àti ìrètí

Báyìí ni Olúwa :

"̀run ni ìtẹ́ mi,

ayé ni àpótí ìtìsẹ̀ mi.

Níbo ni ilé ó kọ́ fún mi ?

Níbo ibi ìsinmi mi yóò gbé ?

í ha á ṣe ọwọ́ mi ṣe nǹkan wọ̀nyí,

bẹ́̀ ni wọ́n ?"

ni Olúwa .

"Eléyìí ni ẹni mo :

ẹni náà ó rẹra rẹ̀ sílẹ̀ ó kẹ́dùn ọkàn rẹ̀,

ó wárìrì ̀rọ̀ mi.

Nígbà Jakọbu lójú oorun rẹ̀, ó nínú ara rẹ̀ , "Dájúdájú Olúwa ń bẹ ìhín yìí, èmi mọ̀." ̀á, ó , "Ìhín yìí ̀gidigidi; ibí í ṣe ibòmíràn ṣe ilé Ọlọ́run, àní ẹnu ibodè ̀run nìyìí."

Seja o primeiro
Publicidade
Bíblia Online Bíblia Online

Bíblia Online • Versão: 2026-06-28_14-13-17-