Publicidade

Salmos 65

Fún adarí orin. Saamu ti Dafidi. Orin.

1 Ìyìn ń dúró ́, Ọlọ́run, Sioni;

ni a ó ̀jẹ́ wa ṣẹ.

2 Ìwọ ó ń gbọ́ àdúrà,

gbogbo ènìyàn yóò sọ́dọ̀ rẹ.

3 ̀ràn àìṣedéédéé borí mi ó ṣe ti ìrékọjá wa ni!

Ìwọ ni yóò wẹ̀ wọ́n kúrò.

4 Ìbùkún ni fún àwọn o yàn

o wa láti máa gbé àgọ́ rẹ!

A tẹ́ lọ́rùn pẹ̀ohun rere inú ilé rẹ,

ti tẹmpili mímọ́ rẹ.

5 Ìwọ wa lóhùn pẹ̀ohun ìyanu ti òdodo,

Ọlọ́run olùgbàlà wa,

ẹni ṣe ìgbẹ́kẹ̀gbogbo òpin ayé

àti àwọn ó jìnnà nínú òkun,

6 ìwọ ó òkè nípa agbára rẹ,

odi ara rẹ àmùrè agbára,

7 ẹni ó rírú omi òkun dákẹ́,

ríru ariwo omi wọn,

àti ìdágìrì àwọn ènìyàn.

8 Àwọn ó ń gbé òkèrè bẹ̀,

nítorí àmì rẹ wọ̀n-ọn-nì;

ìwọ ìjáde òwúrọ̀ àti ti àṣálẹ́ yọ̀,

ìwọ fún orin ayọ̀.

9 Ìwọ bẹ ayé , o bomirin;

ìwọ un ̀rọ̀ púpọ̀.

Odò Ọlọ́run kún fún omi

láti pèsè ọkà fún àwọn ènìyàn,

nítorí ibẹ̀ ni ìwọ ti yàn án.

10 Ìwọ fi bomirin aporo rẹ̀

ìwọ tẹ́ ògúlùtu rẹ̀;

ìwọ fi òjò ilẹ̀ rẹ̀ rọ̀,

o bùkún ̀gbìn rẹ̀.

11 Ìwọ fi oore rẹ ọdún adé,

̀ń kán ipa ̀rẹ.

12 Pápá tútù aginjù ń kan

àwọn òkè kéékèèké fi ayọ̀ di ara wọn àmùrè.

13 Agbo ẹran ni a fi wọ pápá tútù náà aṣọ;

àfonífojì ni a fi ọkà mọ́lẹ̀,

wọ́n fún ayọ̀, wọ́n ń kọrin pẹ̀.

Veja também

Publicidade
Bíblia Online Bíblia Online

Bíblia Online • Versão: 2026-06-28_14-13-17-