Publicidade

Salmos 52

Fún adarí orin. Maskili ti Dafidi. Nígbà Doegi ará Edomu tọ Saulu lọ láti sọ fún , "Dafidi ilé Ahimeleki."

1 Èéṣe ìwọ fi ń ṣe féfé nínú ìwà ìkà, ìwọ alágbára ọkùnrin?

Èéṣe ìwọ fi ń gbéraga nígbà gbogbo,

ìwọ ẹni ̀gàn níwájú Ọlọ́run?

2 Ahọ́n rẹ̀ ń gbìmọ̀ ìparun;

ó dàbí abẹ mímú,

ìwọ ẹni ń hùwà ̀tàn.

3 Ìwọ fẹ́ràn ibi ju ìre lọ,

àti èké ju ó sọ òtítọ́ lọ.

4 Ìwọ fẹ́ràn ̀rọ̀ ìpanilára gbogbo,

ìwọ ahọ́n ̀tàn!

5 Ọlọ́run yóò ́ bolẹ̀ láéláé,

yóò ́ ,

yóò kúrò ni ibùjókòó rẹ,

yóò ́ tu kúrò lórí ilẹ̀ alààyè. Sela.

6 Àwọn olódodo yóò , wọn yóò bẹ̀

wọn yóò rẹ́rìn-ín rẹ̀, ,

7 "Èyí ni ọkùnrin náà ti fi Ọlọ́run ṣe agbára rẹ̀,

ṣe ni ̀pọ̀lọpọ̀ ọrọ̀ rẹ̀ ni ó gbẹ́kẹ̀,

ó mu ara rẹ̀ le nínú ìwà búburú rẹ̀."

8 Ṣùgbọ́n èmi dàbí igi Olifi

ó gbilẹ̀ nínú ilé Ọlọ́run;

èmi gbẹ́kẹ̀ìfẹ́ Ọlọ́run í kùnà

láé àti láéláé.

9 Èmi yóò yìn títí fún ohun ó ti ṣe;

èmi ìrètí nínú orúkọ rẹ,

nítorí orúkọ rẹ dára.

Èmi yóò yìn ́ níwájú àwọn ènìyàn mímọ́.

Veja também

Publicidade
Bíblia Online Bíblia Online

Bíblia Online • Versão: 2026-06-28_14-13-17-