Publicidade

Isaías 66

Ìdájọ́ àti ìrètí

1 Báyìí ni Olúwa :

"̀run ni ìtẹ́ mi,

ayé ni àpótí ìtìsẹ̀ mi.

Níbo ni ilé ó kọ́ fún mi ?

Níbo ibi ìsinmi mi yóò gbé ?

2 í ha á ṣe ọwọ́ mi ṣe nǹkan wọ̀nyí,

bẹ́̀ ni wọ́n ?"

ni Olúwa .

"Eléyìí ni ẹni mo :

ẹni náà ó rẹra rẹ̀ sílẹ̀ ó kẹ́dùn ọkàn rẹ̀,

ó wárìrì ̀rọ̀ mi.

3 Ṣùgbọ́n ẹni ó fi akọ màlúù ẹbọ

ó dàbí ẹni ó pa ènìyàn kan

àti ẹni ó fi ̀dọ́-àgùntàn kan tọrẹ,

dàbí ẹni ó bẹ́ ajá kan lọ́rùn;

ẹnikẹ́ni ó fi irúgbìn ìyẹ̀fun tọrẹ

dàbí ẹni ó ̀jẹ̀ ẹlẹ́dẹ̀ ,

ẹni ó sun tùràrí ìrántí,

dàbí ẹni ó súre fún òrìṣà.

Wọ́n ti yan ipa ̀wọ́n,

ọkàn wọn pẹ̀láyọ̀ nínú ohun ìríra wọn,

4 fún ìdí èyí ni èmi pẹ̀yóò ṣe fi ọwọ́ líle wọn

n ó ohun wọ́n bẹ̀rẹ̀ sórí wọn.

Nítorí nígbà mo , ẹni ó dáhùn,

nígbà mo sọ̀rọ̀, ẹnikẹ́ni tẹ́sílẹ̀.

Wọ́n ṣe ohun búburú ojú mi

wọ́n yan ohun mo kórìíra rẹ̀."

5 gbọ́ ̀rọ̀ Olúwa,

̀yin ń wárìrì nípasẹ̀ ̀rọ̀ rẹ̀:

"Àwọn arákùnrin yín wọ́n kórìíra yín,

wọ́n ta yín nítorí orúkọ mi, ,

Jẹ́ a yin Olúwa lógo,

a le ayọ̀ yín!

Ṣùgbọ́n àwọn ni ojú yóò .

6 Gbọ́ rògbòdìyàn láti ìlú ,

gbọ́ ariwo náà láti tẹmpili !

Ariwo Olúwa í ṣe

ó ń san án fún àwọn ̀rẹ̀ ohun

ó tọ́ wọn.

7 "ó lọ ìrọbí,

ó ti bímọ;

ó di ìrora a,

ó ti ọmọkùnrin.

8 Ta ni ó ti gbọ́ irú nǹkan bẹ́̀ ?

Ta ni ó ti irú nǹkan bẹ́̀ ?

Ǹjẹ́ a le orílẹ̀-èdè kan níjọ́ kan

tàbí orílẹ̀-èdè lalẹ̀ìṣẹ́kan?

Síbẹ̀síbẹ̀ Sioni bẹ̀rẹ̀ rírọbí

bẹ́̀ ni ó àwọn ọmọ rẹ̀.

9 Ǹjẹ́ èmi a ha máa ìrọbí

èmi ni ?"

ni Olúwa .

"Ǹjẹ́ èmi a ha máa ṣé ilé ọmọ

nígbà mo ń ìbí ?"

Ni Ọlọ́run yín .

10 "Jerusalẹmu yọ̀ inú yín ó dùn i,

gbogbo ̀yin fẹ́ràn rẹ̀;

yọ̀ gidigidi pẹ̀rẹ̀,

gbogbo ̀yin ó ti kẹ́dùn fún un.

11 Nítorí ̀yin yóò mu o ìtẹ́lọ́rùn

nínú ọmú rẹ̀ ó tu ni lára,

̀yin yóò mu àmuyó

ó gbádùn nínú àkúnwọ́sílẹ̀ ̀pọ̀lọpọ̀ rẹ̀."

12 Nítorí báyìí ni Olúwa :

"Èmi yóò fún un àlàáfíà gẹ́gẹ́ odò

àti ọrọ̀ orílẹ̀-èdè gẹ́gẹ́ ìṣàn omi;

̀yin yóò mu ọmú, a ó gbé yín apá rẹ̀

a ó yín ṣeré orúkún rẹ̀.

13 Gẹ́gẹ́ ìyá ti í tu ọmọ rẹ̀ nínú,

bẹ́̀ ni èmi yóò yín nínú

a ó yín nínú lórí Jerusalẹmu."

14 Nígbà èyí, inú yín yóò dùn

̀yin yóò gbilẹ̀ gẹ́gẹ́ i koríko;

ọwọ́ Olúwa ni a ó sọ di mọ̀ fún àwọn ìránṣẹ́ rẹ̀,

ṣùgbọ́n ìbínú rẹ̀ ni a ó fihàn fún àwọn ̀rẹ̀.

15 Kíyèsi i, Olúwa ń bọ̀ pẹ̀iná

àti kẹ̀kẹ́ ogun rẹ̀ ó dàbí ìjì líle;

òun yóò ìbínú rẹ sọ̀kalẹ̀ pẹ̀ìrunú,

àti ìbáwí rẹ̀ pẹ̀ahọ́n iná.

16 Nítorí pẹ̀iná àti idà

ni Olúwa yóò ṣe ìdájọ́ lórí i gbogbo ènìyàn,

àti ̀pọ̀lọpọ̀ ni àwọn Olúwa yóò pa.

17 "Gbogbo àwọn wọ́n ya ara wọn mímọ́ wọ́n sọ ara wọn di mímọ́ láti lọ sínú ọgbà, wọ́n tẹ̀ẹni ó láàrín àwọn ó jẹ ẹran ẹlẹ́dẹ̀ àti èkúté àti àwọn ohun ìríra mìíràn ni wọn yóò òpin wọn pàdé papọ̀," ni Olúwa .

18 "Àti Èmi, nítorí ìgbésẹ̀ wọn àti èrò wọn, èmi ti múra tán láti àwọn orílẹ̀-èdè àti ahọ́n jọ, wọn yóò wo ògo mi.

19 "Èmi yóò gbé àmì kan kalẹ̀ láàrín wọn, èmi yóò rán díẹ̀ nínú àwọn ó sálà lọ àwọn orílẹ̀-èdè Tarṣiṣi, àwọn ará Libia àti Ludi, Tubali àti ará Giriki, àti àwọn erékùṣù ó jìnnà réré ìgbọ́ nípa òkìkí mi tàbí ó ògo mi. Wọn yóò kéde ògo mi láàrín àwọn orílẹ̀-èdè. 20 Wọn yóò àwọn arákùnrin yín , láti gbogbo orílẹ̀-èdè, òkè mímọ́ mi Jerusalẹmu gẹ́gẹ́ ọrẹ Olúwa lórí ẹṣin, lórí kẹ̀kẹ́ ẹrù àti ọkọ̀-ẹṣin, àti lórí ìbáaka àti ìbákasẹ," ni Olúwa . "Wọn yóò wọn , gẹ́gẹ́ àwọn ọmọ Israẹli ti ọrẹ oníhóró wọn , sínú Tẹmpili Olúwa nínú ohun èlò mímọ́. 21 Àti èmi yóò yan àwọn kan nínú wọn pẹ̀láti jẹ́ àlùfáà àti Lefi," ni Olúwa .

22 "Gẹ́gẹ́ àwọn ̀run tuntun àti ayé tuntun mo yóò ṣe níwájú mi títí láé," ni Olúwa , "Bẹ́̀ ni orúkọ yín àti ìrandíran yín yóò pegedé. 23 Láti oṣù tuntun kan òmíràn àti láti ọjọ́ ìsinmi kan òmíràn, ni gbogbo ọmọ ènìyàn yóò , wọn yóò tẹríba níwájú mi," ni Olúwa . 24 "Wọn yóò jáde lọ wọn yóò lọ wo òkú àwọn wọ́n dìtẹ̀ mi; kòkòrò wọn yóò , bẹ́̀ ni iná wọn ni a yóò pa, bẹ́̀ ni wọn yóò jẹ́ ohun ìríra fún gbogbo ọmọ ènìyàn."

Veja também

Publicidade
Bíblia Online Bíblia Online

Bíblia Online • Versão: 2026-06-28_14-13-17-