Publicidade

Salmos 122

Orin fún ìgòkè. Ti Dafidi.

1 Inú mi dùn nígbà wọ́n fún mi ,

"jẹ́ á lọ sílé Olúwa."

2 Ẹsẹ̀ wa yóò dúró ẹnu ibodè rẹ,

ìwọ Jerusalẹmu.

3 Jerusalẹmu, ìwọ a kọ́ ìlú

o fi ara mọ́ra pọ̀ ṣọ̀kan.

4 Níbi àwọn ̀máa ń gòkè lọ,

àwọn ̀Olúwa,

̀fún Israẹli,

láti máa dúpẹ́ fún orúkọ Olúwa.

5 Nítorí ibẹ̀ ni a gbé ìtẹ́ ìdájọ́ kalẹ̀,

àwọn ìtẹ́ ilé Dafidi.

6 Gbàdúrà fún àlàáfíà Jerusalẹmu;

àwọn ó fẹ́ yóò ṣe rere.

7 àlàáfíà ó nínú odi rẹ̀,

àti ìre nínú ààfin rẹ̀.

8 Nítorí àwọn ọkùnrin àti àwọn ẹgbẹ́ mi

èmi yóò nísinsin yìí ,

àlàáfíà ó nínú rẹ̀.

9 Nítorí ilé Olúwa Ọlọ́run wa,

èmi yóò máa ìre rẹ̀.

Veja também

Publicidade
Bíblia Online Bíblia Online

Bíblia Online • Versão: 2026-06-28_14-13-17-