Publicidade

Gênesis 28

1 Nítorí náà Isaaki pe Jakọbu, ó súre fún un, ó pàṣẹ fún un , "Ìwọ gbọdọ̀ fẹ́ aya láàrín àwọn ọmọbìnrin Kenaani. 2 Dípò bẹ́̀ lọ Padani-Aramu, ilé Betueli, baba ìyá rẹ, ìwọ ó fẹ́ aya fún ara rẹ nínú àwọn ọmọbìnrin Labani arákùnrin ìyá rẹ. 3 Ọlọ́run Olódùmarè El-Ṣaddai ó bùkún fún , ó i, ó pọ̀ i iye títí ìwọ yóò di àgbájọ àwọn ènìyàn. 4 Ọlọ́run ó fún ìwọ àti irú-ọmọ rẹ ìre ó fún Abrahamu, ìwọ ó le gba ilẹ̀ níbi a ti ń ṣe àtìpó yìí, ilẹ̀ Ọlọ́run ti fi fún Abrahamu." 5 Bẹ́̀ ni Isaaki rán Jakọbu lọ. Ó lọ Padani-Aramu, lọ́dọ̀ Labani ọmọ Betueli, ará Aramu, í ṣe arákùnrin Rebeka ìyá Jakọbu àti Esau.

6 Nígbà Esau gbọ́ , Isaaki ti súre fún Jakọbu, ó ti rán Jakọbu lọ Padani-Aramu láti fẹ́ aya níbẹ̀ àti nígbà ó súre fún un, ó kìlọ̀ fun un , gbọdọ̀ fẹ́ nínú àwọn ọmọbìnrin Kenaani 7 àti , Jakọbu ti gbọ́rọ̀ ìyá àti baba rẹ̀ lẹ́nu, ó ti lọ Padani-Aramu. 8 Nígbà náà ni Esau mọ Isaaki baba rẹ ti kórìíra àwọn ọmọbìnrin Kenaani . 9 Nítorí náà Esau tọ Iṣmaeli lọ, ó fẹ́ Mahalati, arábìnrin Nebaioti, ọmọbìnrin Iṣmaeli í ṣe ọmọ Abrahamu. Ó fẹ́ , kún àwọn ìyàwó ó ti tẹ́lẹ̀.

Àlá Jakọbu Beteli

10 Jakọbu kúrò Beerṣeba, ó kọrí ìlú Harani. 11 Nígbà ó ibìkan, ó dúró òru náà nítorí ilẹ̀ ti ń ṣú, ó gbé òkúta kan ó fi ṣe ìrọ̀, ó sùn. 12 Ó àlá , a gbé àkàsọ̀ kan dúró ti ó fi ìdí lélẹ̀, orí rẹ̀ kan ̀run, àwọn angẹli Ọlọ́run ń gòkè, wọ́n ń sọ̀kalẹ̀ lórí rẹ̀. 13 Olúwa dúró lókè rẹ̀, ó , "Èmi ni Olúwa, Ọlọ́run baba rẹ Abrahamu àti Ọlọ́run Isaaki, ìwọ àti ìran rẹ ni èmi yóò fi ilẹ̀ ìwọ dùbúlẹ̀ sórí rẹ̀ yìí fún. 14 Ìran rẹ yóò pọ̀ erùpẹ̀ ilẹ̀, ìwọ yóò tànkálẹ̀ ìlà-oòrùn àti ìwọ̀-oòrùn, àti gúúsù àti àríwá. A ó bùkún gbogbo orílẹ̀-èdè ayé nípasẹ̀ ìwọ àti àwọn ọmọ rẹ. 15 Èmi pẹ̀rẹ, èmi yóò pa mọ́ ibikíbi ìwọ lọ, èmi yóò padà ilẹ̀ yìí àlàáfíà. Èmi yóò fi sílẹ̀ ìgbà kan, títí èmi yóò fi gbogbo ìlérí mi ṣẹ."

16 Nígbà Jakọbu lójú oorun rẹ̀, ó nínú ara rẹ̀ , "Dájúdájú Olúwa ń bẹ ìhín yìí, èmi mọ̀." 17 ̀á, ó , "Ìhín yìí ̀gidigidi; ibí í ṣe ibòmíràn ṣe ilé Ọlọ́run, àní ẹnu ibodè ̀run nìyìí."

18 Jakọbu dìde kùtùkùtù òwúrọ̀, ó gbé òkúta ó fi ṣe ìrọ̀lélẹ̀ ̀wọ́n, ó da òróró si lórí. 19 Ó pe orúkọ ibẹ̀ Beteli, ó tilẹ̀ jẹ́ ìlú náà ń jẹ́ Lusi tẹ́lẹ̀ .

20 Jakọbu jẹ́ ̀jẹ́ níbẹ̀ , "Ọlọ́run yóò pẹ̀mi, yóò pa mọ́ ìrìnàjò mi mo ń lọ, yóò fún mi oúnjẹ láti jẹ àti aṣọ láti wọ̀, 21 mo padà sílé baba mi àlàáfíà, nígbà náà Olúwa ni yóò jẹ́ Ọlọ́run mi, 22 Òkúta yìí mo gbé kalẹ̀ ̀wọ́n yóò jẹ́ ilé Ọlọ́run, nínú gbogbo ohun ìwọ ó fi fún mi, èmi yóò fi ìdámẹ́wàá rẹ̀ fún ."

Veja também

Publicidade
Bíblia Online Bíblia Online

Bíblia Online • Versão: 2026-06-28_14-13-17-