Publicidade

Conversão

Por Bíblia Online

A conversão é o ato de se voltar para Deus — arrependendo-se do pecado e abraçando a graça. É o início de uma vida nova, transformada pelo amor de Cristo.

Arrependei-vos

Arrependei-vos e convertei-vos para que os vossos pecados sejam apagados. A conversão começa com a mudança de mente e coração.

Nítorí náà ronúpìwàdà, yípadà Ọlọ́run, a pa ̀ṣẹ̀ yín rẹ́, àkókò ìtura a ti ̀dọ̀ Olúwa ,

Peteru fún wọn , "ronúpìwàdà, a bamitiisi olúkúlùkù yín orúkọ Jesu Kristi fún ìdáríjì ̀ṣẹ̀ yín. ̀yin yóò gba ̀bùn ̀Mímọ́.

Pẹ̀lúpẹ̀ìgbà àìmọ̀ yìí ni Ọlọ́run fojú ; ṣùgbọ́n nísinsin yìí ó pàṣẹ fún gbogbo ènìyàn níbi gbogbo láti ronúpìwàdà.

Láti ìgbà náà lọ ni Jesu ti bẹ̀rẹ̀ wàásù: "ronúpìwàdà, nítorí ìjọba ̀run dẹ̀dẹ̀."

so èso ó yẹ fún ìrònúpìwàdà.

Ó kéde , "Àkókò náà wàyí, ìjọba Ọlọ́run dẹ̀dẹ̀. yípadà kúrò nínú ̀ṣẹ̀ yín, gba ìyìnrere yìí gbọ́."

O amor de Deus converte

Céu se alegra por um pecador que se arrepende. Deus não deseja a morte do ímpio, mas que se converta e viva.

Mo fún yín, gẹ́gẹ́ bẹ́̀ ni ayọ̀ yóò ̀run lórí ẹlẹ́ṣẹ̀ kan ó ronúpìwàdà, ju lórí olóòtítọ́ mọ́kàndínlọ́gọ́rùn-ún lọ, nílò ìrònúpìwàdà.

Mo fún yín, gẹ́gẹ́ bẹ́̀ ni ayọ̀ ń bẹ níwájú àwọn angẹli Ọlọ́run lórí ẹlẹ́ṣẹ̀ kan ó ronúpìwàdà."

Èmí láti pe àwọn olódodo ṣe àwọn ẹlẹ́ṣẹ̀ ìrònúpìwàdà."

Nítorí inú mi dùn ikú ẹnikẹ́ni ni Olúwa Olódùmarè . Nítorí náà, yípadà !

"Ṣùgbọ́n ènìyàn búburú yípadà kúrò nínú gbogbo ̀ṣẹ̀ rẹ̀ ti , bẹ̀rẹ̀ í pa àṣẹ mi mọ́, ń ṣe ohun tọ́ àti ohun yẹ, nítòótọ́ ni yóò , .

Ọkàn o sẹ̀ ni yóò

̀rọ̀ Olúwa tún tọ̀ : "Kín ni ̀yin ̀yin fi ń pa òwe nípa Israẹli :

" Àwọn baba ti jẹ èso àjàrà kíkan,

eyín àwọn ọmọ kan.

"mo ti láààyè ni Olúwa Olódùmarè , ̀yin yóò pa òwe yìí mọ́ ni Israẹli. Nítorí èmi gbogbo ọkàn, ọkàn baba tèmi bẹ́̀ ni ọkàn ọmọ pàápàá jẹ tèmi, ọkàn ṣẹ̀ yóò .

"ọkùnrin olódodo kan ,

ń ṣe ohun tọ́, yẹ

wọn jẹun lórí òkè gíga,

gbójú rẹ̀ sókè àwọn òrìṣà ilẹ̀ Israẹli,

ti ba obìnrin aládùúgbò rẹ̀ jẹ́

tàbí ó sùn ti obìnrin ni àsìkò èérí rẹ̀.

ni ẹnikẹ́ni lára,

ó sanwó fún onígbèsè rẹ̀

gẹ́gẹ́ ṣe ṣe ìlérí fún un,

fi ipá jalè

ṣùgbọ́n ó fún ẹni ebi ń pa oúnjẹ,

ó fi ̀wọ àwọn ó ìhòhò.

Ẹni fi fún ni láti gba ̀,

tàbí gba èlé pọ̀.

Ó yọ ọwọ́ rẹ̀ kúrò nínú ìwà ̀ṣẹ̀,

ó ń ṣe ìdájọ́ òtítọ́ láàrín ọkùnrin kan àti èkejì rẹ̀.

ó ń tẹ̀àṣẹ mi,

ó ń pa òfin mi mọ́ lóòtítọ́ àti lódodo.

Ó jẹ́ olódodo,

yóò nítòótọ́,

Olúwa Olódùmarè .

"ó bi ọmọkùnrin, oníwà ipá, ń jalè, tún ń pànìyàn, ń ṣe gbogbo àwọn nǹkan wọ̀nyí arákùnrin rẹ̀ (ṣe ̀kan nínú gbogbo iṣẹ́ wọ̀n-ọn-nì):

"Ó ń jẹun lójúbọ lórí òkè gíga,

ó ba obìnrin aládùúgbò rẹ̀ jẹ́.

Ó ni àwọn tálákà àti aláìní lára,

ó ń fipá jalè, í padà gẹ́gẹ́ ìlérí,

o gbójú sókè òrìṣà,

ó ń ṣe ohun ìríra.

Ó ń fi owó ya ni pẹ̀èlé, ó tún ń gba èlé pọ̀.

Ǹjẹ́ irú ọkùnrin yìí wa le è ? Òun yóò láààyè! Nítorí òun ti ṣe àwọn ohun ìríra yìí, kíkú ni yóò , ̀jẹ̀ rẹ yóò lórí rẹ̀.

"ọkùnrin yìí bímọ ọkùnrin, gbogbo ̀ṣẹ̀ ti baba rẹ ń ṣẹ̀ yìí, bẹ̀, ti ṣe irú rẹ̀:

"jẹun lójúbọ lórí òkè gíga

tàbí gbójú sókè àwọn òrìṣà ilé Israẹli,

ba obìnrin aládùúgbò rẹ̀ jẹ́

ni ẹnikẹ́ni lára,

ohun ògo dúró

gba èlé tàbí fipá jalè

ṣùgbọ́n ó ń fún ẹni tébi ń pa lóúnjẹ,

fi aṣọ bo àwọn oníhòhò.

Ó ń yọ ọwọ́ rẹ kúrò nínú ̀ṣẹ̀,

gba èlé tàbí èlé pọ̀,

ó ń pa òfin mi mọ́,

ó ń tẹ̀àwọn àṣẹ mi.

fún ̀ṣẹ̀ baba rẹ̀, nítòótọ́ yóò ! Ṣùgbọ́n baba rẹ̀ ni yóò fún ̀ṣẹ̀ ara rẹ̀, nítorí ó jẹ́ arẹ́nijẹ, ó jalè arákùnrin rẹ, ó ṣe ohun dára láàrín àwọn ènìyàn rẹ̀.

"Síbẹ̀, tún ń béèrè , ti ọmọ fi í ru ̀bi baba rẹ̀?’ Níwọ́n ìgbà ọmọ ti ṣe ohun tọ́, yẹ, ti kíyèsi ara láti pa gbogbo àṣẹ mi mọ́, nítòótọ́ ni yóò . Ọkàn ó ṣẹ̀ yóò . Ọmọ í ru ̀bi baba rẹ̀, bẹ́̀ ni baba náà ru ̀bi ọmọ rẹ̀. Ìwà rere ènìyàn rere yóò lórí rẹ̀, ìwà búburú ti ènìyàn búburú náà la ó i lọ́rùn.

"Ṣùgbọ́n ènìyàn búburú yípadà kúrò nínú gbogbo ̀ṣẹ̀ rẹ̀ ti , bẹ̀rẹ̀ í pa àṣẹ mi mọ́, ń ṣe ohun tọ́ àti ohun yẹ, nítòótọ́ ni yóò , . A rántí gbogbo ̀ṣẹ̀ rẹ ti tẹ́lẹ̀ láti á lọ́rùn nítorí ìwà òdodo rẹ fihàn, yóò . Ǹjẹ́ èmi ha ni inú dídùn si ikú ènìyàn búburú í? Olúwa Olódùmarè , dípò èyí inú mi ha ni i dùn nígbà ba yípadà kúrò ni àwọn ̀búburú rẹ̀ ó ?

"Ṣùgbọ́n ènìyàn rere yípadà kúrò ni ̀òdodo rẹ̀ ń dẹ́ṣẹ̀, ó tún ń ṣe àwọn ohun ìríra ènìyàn búburú ń ṣe, yóò wa ? A yóò rántí ̀kankan nínú ìwà rere rẹ̀ mọ́, nítorí ó ti jẹ̀bi ìwà àrékérekè àti ̀ṣẹ̀ , yóò .

"Bẹ́̀ ni, ̀yin tún , ̀Olúwa gún.Gbọ́ nísinsin yìí, ìwọ ilé Israẹli. ̀mi ni ha gún? í wa ṣé ̀tiyín gan an ni gún? olódodo ba yípadà kúrò nínú olódodo rẹ̀, dẹ́ṣẹ̀, yóò ku fún ̀ṣẹ̀ rẹ̀, yóò nítorí ̀ṣẹ̀ ti . Ṣùgbọ́n bi ènìyàn búburú yípadà kúrò nínú ìwà búburú ti ṣe, ṣe ohun tọ́ àti ohun yẹ, yóò gba ̀rẹ̀ . Nítorí ó ronú lórí gbogbo ̀ṣẹ̀ ti , ó yípadà kúrò nínú wọn, nítòótọ́ ni yóò ; yóò . Síbẹ̀, ilé Israẹli , ̀Olúwa gún.̀mi ha tọ́ ilé Israẹli? í wa ṣe ̀tiyín gan an ni ko gún?

"Nítorí náà, ilé Israẹli, èmi yóò da yín lẹ́jọ́, gẹ́gẹ́ ̀ẹnìkọ̀̀kan yín ṣe ni Olúwa Olódùmarè . yípadà! si kúrò nínú gbogbo ̀ṣẹ̀ yín, bẹ́̀ ni ìrékọjá yóò jẹ́ ̀ìṣubú yín. kọ̀ gbogbo ̀ṣẹ̀ ti ti sílẹ̀, gba ọkàn àti ̀tuntun. Nítorí fi máa , ilé Israẹli? Nítorí inú mi dùn ikú ẹnikẹ́ni ni Olúwa Olódùmarè . Nítorí náà, yípadà !

Olúwa fi ìlérí rẹ̀ jáfara, àwọn ẹlòmíràn ti ka ìjáfara ; ṣùgbọ́n ó ń sùúrù fún yín nítorí fẹ́ ẹnikẹ́ni ṣègbé, ṣe gbogbo ènìyàn ìrònúpìwàdà.

Transformação

Voltai-vos para mim e sereis salvos! Rasgai o coração e não as vestes. A verdadeira conversão transforma o interior.

Jẹ́ ìkà ó kọ ̀rẹ̀ sílẹ̀

àti ènìyàn búburú èrò rẹ̀.

Jẹ́ ó yípadà Olúwa, Òun yóò ṣàánú fún un,

àti Ọlọ́run wa, nítorí Òun yóò dáríjì.

Èmi ti gbá gbogbo ìkùnà rẹ dànù i kurukuru,

àwọn ̀ṣẹ̀ rẹ ìrì òwúrọ̀.

Padà sọ́dọ̀ mi,

nítorí mo ti ́ padà."

Fa ọkàn rẹ ya

"Ǹjẹ́ nítorí náà nísinsin yìí," ni Olúwa ,

"fi gbogbo ọkàn yín yípadà mi,

àti pẹ̀àwẹ̀, àti pẹ̀ẹkún, àti pẹ̀̀fọ̀."

fa ọkàn yín ya,

í í ṣe aṣọ yín,

yípadà Olúwa Ọlọ́run yín,

nítorí o pọ̀ oore-ọ̀fẹ́,

ó kún fun àánú, ó lọ́ra láti bínú,

ó ṣeun púpọ̀, ó ronúpìwàdà láti ṣe búburú.

àwọn ènìyàn, a fi orúkọ mi , wọ́n rẹ ara wọn sílẹ̀, wọ́n gbàdúrà, wọ́n ojú mi, wọ́n kúrò nínú ̀búburú wọn, nígbà náà, èmi yóò gbọ́ láti ̀run, èmi yóò dárí ̀ṣẹ̀ wọn wọ́n èmi yóò wo ilẹ̀ wọn sàn.

Hesekiah ṣe àsè ìrékọjá

Hesekiah ránṣẹ́ gbogbo Israẹli àti Juda, ó kọ ìwé Efraimu àti Manase, wọn ó sínú ilé Olúwa Jerusalẹmu láti pa àjọ ìrékọjá mọ́ Olúwa Ọlọ́run Israẹli. Nítorí ọba ti gbìmọ̀ àti àwọn ìjòyè rẹ̀, àti gbogbo ìjọ ènìyàn Jerusalẹmu, láti pa àjọ ìrékọjá mọ́ oṣù kejì. Nítorí wọn pa á mọ́ àkókò náà, nítorí àwọn àlùfáà i ya ara wọn mímọ́ ; bẹ́̀ ni àwọn ènìyàn ì ara wọn jọ Jerusalẹmu. ̀rọ̀ náà tọ́ lójú ọba àti lójú gbogbo ìjọ ènìyàn. Bẹ́̀ ni wọ́n fi àṣẹ kan lélẹ̀, láti kéde gbogbo Israẹli láti Beerṣeba àní títí Dani, láti pa àjọ ìrékọjá mọ́ Olúwa Ọlọ́run Israẹli Jerusalẹmu: nítorí wọn pa á mọ́ ọjọ́ púpọ̀ gẹ́gẹ́ a ti kọ ́.

Bẹ́̀ àwọn oníṣẹ́ ń sáré lọ pẹ̀ìwé láti ọwọ́ ọba àti àwọn ìjòyè rẹ̀ gbogbo Israẹli àti Juda; àti gẹ́gẹ́ àṣẹ ọba, ,

"̀yin ọmọ Israẹli padà Olúwa Ọlọ́run Abrahamu, Isaaki, àti Israẹli, òun ó yípadà àwọn ìyókù nínú yín, ó sálà kúrò lọ́wọ́ àwọn ọba Asiria. ̀yin ó ṣe dàbí àwọn baba yín, àti àwọn arákùnrin yín ó dẹ́ṣẹ̀ Olúwa, Ọlọ́run àwọn baba wọn, nítorí náà ó ṣe fi wọ́n fún ìdahoro ̀yin ti . Ǹjẹ́ ̀yin ó ṣe ṣe ọlọ́rùn líle, àwọn baba yín, ṣùgbọ́n jọ̀wọ́ ara yín lọ́wọ́ fún Olúwa, wọ inú ibi mímọ́ rẹ̀ lọ, ti òun ti ìyàsímímọ́ títí láé. sin Olúwa, Ọlọ́run yín gbígbóná ìbínú rẹ̀ ó yípadà kúrò ̀dọ̀ yín. Nítorí ̀yin tún yípadà Olúwa, àwọn arákùnrin yín, àti àwọn ọmọ yín, yóò àánú níwájú àwọn ó wọn ìgbèkùn lọ, wọn ó tún padà ilẹ̀ : nítorí Olúwa Ọlọ́run yín, oníyọnu àti aláàánú ni, yóò ojú rẹ̀ padà kúrò lọ́dọ̀ yín, ̀yin padà sọ́dọ̀ rẹ̀."

Bẹ́̀ ni àwọn oníṣẹ́ náà kọjá láti ìlú ìlú, ilẹ̀ Efraimu àti Manase títí Sebuluni, ṣùgbọ́n wọ́n fi wọ́n rẹ́rìn-ín ẹlẹ́, wọ́n gàn wọ́n. Síbẹ̀ òmíràn nínú àwọn ènìyàn Aṣeri àti Manase àti Sebuluni rẹ̀ ara wọn sílẹ̀, wọ́n Jerusalẹmu. Juda pẹ̀, ọwọ́ Ọlọ́run láti fún wọn ọkàn kan láti pa òfin ọba mọ́ àti àwọn ìjòyè, nípa ̀rọ̀ Olúwa.

̀pọ̀lọpọ̀ ènìyàn péjọ Jerusalẹmu, láti pa àjọ àkàrà àìwú mọ́ oṣù kejì. Wọ́n dìde, wọ́n gbogbo pẹpẹ ó Jerusalẹmu lọ, àti gbogbo pẹpẹ tùràrí ni wọ́n lọ, wọ́n wọ́n odò Kidironi.

Nígbà náà ni wọ́n pa ẹran ìrékọjá náà ọjọ́ kẹrìnlá oṣù kejì: ojú ti àwọn àlùfáà àti àwọn ọmọ Lefi, wọ́n ara wọn mímọ́, wọ́n ẹbọ sísun sínú ilé Olúwa. Wọ́n dúró ipò wọn, ètò wọn gẹ́gẹ́ òfin Mose, ènìyàn Ọlọ́run: àwọn àlùfáà wọ́n ̀jẹ̀ náà, wọ́n gbà lọ́wọ́ àwọn ọmọ Lefi. Nítorí ̀pọ̀lọpọ̀ ni ó nínú ìjọ ènìyàn náà ara wọn mímọ́: nítorí náà ni àwọn ọmọ Lefi ṣe ń tọ́àti pa ẹran ìrékọjá fún olúkúlùkù ẹni ó ṣe aláìmọ́, láti á mímọ́ Olúwa. ̀pọ̀lọpọ̀ ènìyàn, àní ̀pọ̀lọpọ̀ nínú Efraimu àti Manase, Isakari, àti Sebuluni wẹ̀ ara wọn mọ́ síbẹ̀ wọ́n jẹ ìrékọjá náà, í ṣe gẹ́gẹ́ a ti kọ ́. Ṣùgbọ́n Hesekiah bẹ̀bẹ̀ fún wọn, , Olúwa, ẹni rere, dáríjì olúkúlùkù, ó múra ọkàn rẹ̀ láti Ọlọ́run, Olúwa Ọlọ́run àwọn baba rẹ̀ ṣùgbọ́n í ṣe nípa ìwẹ̀nùmọ́ mímọ́ Olúwa gbọ́ ti Hesekiah, ó àwọn ènìyàn náà láradá.

Àwọn ọmọ Israẹli a Jerusalẹmu fi ayọ̀ ńlá pa àjọ àkàrà àìwú mọ́ ọjọ́ méje: àwọn ọmọ Lefi, àti àwọn àlùfáà yin Olúwa lójoojúmọ́, wọ́n ń fi ohun èlò olóhùn gooro kọrin Olúwa.

Hesekiah sọ̀rọ̀ ìtùnú fún gbogbo àwọn ọmọ Lefi, ó lóye ìmọ̀ rere Olúwa: ọjọ́ méje ni wọ́n fi jẹ àsè náà wọ́n ẹbọ àlàáfíà, wọ́n ń fi ohùn rara dúpẹ́ fún Olúwa, Ọlọ́run àwọn baba wọn.

Gbogbo ìjọ náà gbìmọ̀ láti pa ọjọ́ méje mìíràn mọ́: wọ́n fi ayọ̀ pa ọjọ́ méje mìíràn mọ́. Nítorí Hesekiah, ọba Juda, ta ìjọ ènìyàn náà ọrẹ, ẹgbẹ̀rún (1,000) akọ màlúù, àti ̀́dẹ́gbàárin (7,000) àgùntàn. ̀pọ̀lọpọ̀ nínú àwọn àlùfáà ya ara wọn mímọ́. Gbogbo ìjọ ènìyàn Juda pẹ̀àwọn àlùfáà àti àwọn ọmọ Lefi, àti gbogbo ìjọ ènìyàn ó ti inú Israẹli jáde , àti àwọn àjèjì ó ti ilẹ̀ Israẹli jáde , àti àwọn ń gbé Juda yọ̀. Bẹ́̀ ni ayọ̀ ńlá Jerusalẹmu: nítorí láti ọjọ́ Solomoni, ọmọ Dafidi, ọba Israẹli, irú èyí Jerusalẹmu. Nígbà náà ni àwọn àlùfáà, àwọn ọmọ Lefi dìde, wọ́n súre fún àwọn ènìyàn náà: a gbọ́ ohùn wọn, àdúrà wọn gòkè lọ si ibùgbé mímọ́ rẹ̀, àní ̀run.

Ìpè láti padà ̀dọ̀ Ọlọ́run

oṣù kẹjọ ọdún kejì ọba Dariusi, ̀rọ̀ Olúwa tọ wòlíì Sekariah ọmọ Berekiah, ọmọ Iddo :

"Olúwa ti bínú àwọn baba ńlá yín. Nítorí náà sọ fún àwọn ènìyàn. Èyí ni ohun Olúwa àwọn ọmọ-ogun : padà ̀dọ̀ mi,báyìí Olúwa àwọn ọmọ-ogun , èmi náà yóò padà ̀dọ̀ yín,ni Olúwa àwọn ọmọ-ogun . dàbí àwọn baba yín, àwọn àwọn wòlíì ìṣáájú ti , báyìí Olúwa àwọn ọmọ-ogun , yípadà nísinsin yìí kúrò ̀búburú yín,àti kúrò nínú ìwà búburú yín; ṣùgbọ́n wọn gbọ́, bẹ́̀ ni wọn fetí ti èmi, ni Olúwa . Àwọn baba yín, níbo ni wọ́n ? Àti àwọn wòlíì, wọ́n ha títí ayé? Ṣùgbọ́n ̀rọ̀ mi àti ìlànà mi, ti mo pa àṣẹ fún àwọn ìránṣẹ́ mi wòlíì, ha tún àwọn baba yín?

"Wọ́n padà wọ́n , Gẹ́gẹ́ Olúwa àwọn ọmọ-ogun ti láti ṣe wa, gẹ́gẹ́ bi ̀wa, àti gẹ́gẹ́ ìṣe wa, bẹ́̀ o ti ṣe wa.’ "

Ènìyàn láàrín àwọn igi miritili

ọjọ́ kẹrìnlélógún oṣù kọkànlá, ó jẹ́, oṣù Sebati, ọdún kejì Dariusi, ni ̀rọ̀ Olúwa tọ wòlíì Sekariah, ọmọ Berekiah ọmọ Iddo , .

Mo ìran kan ni òru, si ó, ọkùnrin kan ń gun ẹṣin pupa kan, òun dúró láàrín àwọn igi maritili ó ibi òòji; lẹ́yìn rẹ̀ ni ẹṣin pupa, adíkálà, àti funfun gbé .

Nígbà náà ni mo , "ni wọ̀nyí olúwa mi?"

Angẹli ń ba mi sọ̀rọ̀ fún mi , "Èmi ó fi ohun àwọn wọ̀nyí jẹ́ hàn ́."

Ọkùnrin ó dúró láàrín àwọn igi maritili dáhùn ó , "Wọ̀nyí àwọn Olúwa ti rán láti máa rìn sókè sódò ni ayé."

Wọ́n si angẹli Olúwa ó dúró láàrín àwọn igi maritili náà lóhùn , "Àwa ti rìn sókè sódò ayé, àwa ti i gbogbo ayé ìsinmi àti àlàáfíà."

Nígbà náà ni angẹli Olúwa náà dáhùn ó , "Olúwa àwọn ọmọ-ogun, yóò ti pẹ́ ìwọ yóò fi ṣàánú fún Jerusalẹmu, àti fún àwọn ìlú ńlá Juda, ti ìwọ ti bínú ni àádọ́rin ọdún wọ̀nyí?" Olúwa fi ̀rọ̀ rere àti ̀rọ̀ ìtùnú angẹli ń mi sọ̀rọ̀ lóhùn.

Angẹli ti ń mi sọ̀rọ̀ fún mi , "Ìwọ kígbe , báyìí ni Olúwa àwọn ọmọ-ogun , Èmi ń fi ìjowú ńlá jowú fún Jerusalẹmu àti fún Sioni. Èmi bínú púpọ̀púpọ̀ si àwọn orílẹ̀-èdè ó òun ààbò. Nítorí nígbà mo bínú díẹ̀, wọ́n ran ìparun lọ́wọ́ láti tẹ̀síwájú.

"Nítorí náà, báyìí ni Olúwa : Mo padà tọ Jerusalẹmu pẹ̀àánú; ni Olúwa àwọn ọmọ-ogun , a ó kọ́ ilé mi sínú rẹ̀, a o ta okùn ìwọ̀n kan jáde sórí Jerusalẹmu.

"Máa síbẹ̀ , báyìí ni Olúwa àwọn ọmọ-ogun , A o máa fi ìre kún ìlú ńlá mi síbẹ̀; Olúwa yóò máa tu Sioni nínú síbẹ̀, yóò yan Jerusalẹmu síbẹ̀.’ "

Ìwo mẹ́rin àti alágbẹ̀dẹ mẹ́rin

Mo si gbé ojú sókè, mo , kíyèsi i, ìwo mẹ́rin. Mo sọ fún angẹli ó ń mi sọ̀rọ̀ , "ni nǹkan wọ̀nyí?"

Ó si lóhùn , "Àwọn ìwo wọ̀nyí ni ó Juda, Israẹli, àti Jerusalẹmu ."

Olúwa fi alágbẹ̀dẹ mẹ́rin kan hàn . Nígbà náà ni mo , "ni àwọn wọ̀nyí ṣe?"

O sọ , "Àwọn wọ̀nyí ni ìwo ó ti Juda , bẹ́̀ ẹnikẹ́ni fi gbé orí rẹ̀ sókè? Ṣùgbọ́n àwọn wọ̀nyí láti dẹ́rùbà wọ́n, láti ìwo àwọn orílẹ̀-èdè jáde, ti wọ́n gbé ìwo wọn sórí ilẹ̀ Juda láti ènìyàn rẹ̀ ."

Gbogbo àwọn ti èmi fẹ́ ni èmi ń , mo ń : nítorí náà, ìtara, ìwọ ronúpìwàdà.

máa pa ̀ara yín ń bẹ ayé run: àgbèrè, panṣágà, ìwà àìmọ́, ìfẹ́kúfẹ̀́ àti ìwọra, nítorí ìwọ̀nyí jásí ìbọ̀rìṣà.

ṣe jẹ́ ̀ara yín kan di ohun èlò ohun búburú, nípa ̀ṣẹ̀ dídá. Ṣùgbọ́n fi wọn fún Ọlọ́run pátápátá. Wọ́n ti di ààyè, jẹ́ wọn di ohun èlò ọwọ́ Ọlọ́run, ó wọ́n fún àwọn ìlànà rẹ̀ ó dára.

Ṣíṣe dáradára gbogbo ènìyàn

Ará, a tilẹ̀ ènìyàn nínú ̀ṣẹ̀ kan, ̀yin í ṣe ti ̀irú ẹni bẹ́̀ bọ̀ sípò nínú ̀ìwà tútù; ìwọ tìkára rẹ̀ máa kíyèsára, a ba à dán ìwọ náà pẹ̀.

Nítorí náà, lépa láti borí gbogbo èérí àti ìwà búburú ó gbilẹ̀ yíká, fi ọkàn tútù gba ̀rọ̀ náà a gbìn, ó gba ọkàn yín .

Seja o primeiro
Publicidade
Bíblia Online Bíblia Online

Bíblia Online • Versão: 2026-06-28_14-13-17-