Publicidade

Isaías 44

Israẹli a yàn

1 "Ṣùgbọ́n gbọ́ nísinsin yìí, ìwọ Jakọbu ìránṣẹ́ mi,

àti Israẹli, ẹni mo ti yàn.

2 Ohun Olúwa nìyìí

ẹni ó , ẹni ó ti mọ̀ ́n

láti inú ìyá rẹ ,

àti ẹni yóò ràn ́ lọ́wọ́ pẹ̀.

ṣe bẹ̀, ìwọ Jakọbu, ìránṣẹ́ mi,

Jeṣuruni ẹni mo ti yàn.

3 Nítorí èmi yóò da omi ilẹ̀ ń pòǹgbẹ

àti àwọn odò ilẹ̀ gbígbẹ,

Èmi yóò ̀mi ara àwọn ọmọ rẹ,

àti ìbùkún mi sórí àwọn àrọ́mọdọ́mọ rẹ.

4 Wọn yóò dàgbàsókè gẹ́gẹ́ i koríko nínú pápá oko tútù,

àti gẹ́gẹ́ igi Poplari létí odò ń sàn.

5 ̀kan yóò , Èmi jẹ́ ti Olúwa;

òmíràn yóò pe ara rẹ̀ gẹ́gẹ́ orúkọ Jakọbu;

bẹ́̀ ni òmíràn yóò kọ ́ ọwọ́ rẹ̀, Ti Olúwa,

yóò máa jẹ́ orúkọ náà Israẹli.

Olúwa ni, í ṣe ère òrìṣà

6 "Ohun Olúwa nìyìí

ọba Israẹli àti Olùdáǹdè, àní

Olúwa àwọn ọmọ-ogun.

Èmi ni ẹni àkọ́kọ́ àti ẹni ìgbẹ̀yìn,

lẹ́yìn mi Ọlọ́run kan.

7 Ta ni ó dàbí ì mi? Jẹ́ o kéde rẹ̀.

Jẹ́ ó ó gbé síwájú mi

ni ó ti ṣẹlẹ̀ láti ìgbà mo fi ìdí àwọn ènìyàn ìṣẹ̀ǹbáyé kalẹ̀,

àti ni ohun ń ń bọ̀,

bẹ́̀ ni, jẹ́ ó sọ àsọtẹ́lẹ̀ ohun ń bọ̀ .

8 ṣe wárìrì, ṣe bẹ̀.

Ǹjẹ́ èmi ti kéde èyí mo ti sọ

àsọtẹ́lẹ̀ rẹ̀ tipẹ́tipẹ́?

̀yin ni ẹlẹ́rìí mi. Ǹjẹ́ Ọlọ́run kan

ha ń bẹ lẹ́yìn mi?

Bẹ́̀ kọ́, àpáta mìíràn; Èmi mọ ̀kankan."

9 Gbogbo àwọn ń gbẹ́ ère jásí asán,

àti àwọn ohun wọn ń pamọ́

jámọ́ nǹkan kan.

Àwọn yóò sọ̀rọ̀ fún wọn fọ́ lójú;

wọ́n jẹ́ aláìmọ̀kan ìtìjú ara wọn.

10 Ta ni ó mọ òrìṣà kan ó ya ère,

èrè kankan fún un?

11 Òun àti nǹkan rẹ̀ wọ̀nyí ni a ó dójútì;

àwọn oníṣọ̀yàtọ̀, ènìyàn ni wọ́n.

Jẹ́ gbogbo wọn gbárajọ wọ́n

fi ìdúró wọn hàn;

gbogbo wọn ni a ó bọ́ sínú ìpayà àti àbùkù.

12 Alágbẹ̀dẹ ohun èlò,

ó fi ń ṣiṣẹ́ nínú èédú;

ó fi òòlù ya ère kan,

ó ṣe é pẹ̀agbára apá rẹ̀,

ebi ń pa á, àárẹ̀ un;

mu omi rárá, ìrẹ̀wẹ̀a.

13 Gbẹ́nàgbẹ́fi ìwọ̀n wọ́n ́n

ó fi lẹ́̀ṣe àmì ara rẹ̀,

Ó tún fi ìfà a jáde

ó tún fi òsùwọ̀n ṣe àmì i.

Ó gbẹ́ ìrí ènìyàn

gẹ́gẹ́ ènìyàn nínú ògo rẹ̀,

ó máa gbé nínú ilé òrìṣà.

14 Ó igi kedari lulẹ̀,

tàbí bóyá ó sípírẹ́ṣì tàbí igi óákù.

Ó jẹ́ ó dàgbà láàrín àwọn igi inú igbó,

ó le gbin igi páínì, èyí òjò ó dàgbà.

15 Ohun èlò ìdáná ni fún ènìyàn;

díẹ̀ nínú rẹ̀ ni ó láti

ara rẹ̀ lọ́wọ́́rọ́,

ó iná ó fi ṣe àkàrà.

Ṣùgbọ́n bákan náà ni ó ṣe òrìṣà ó ń sìn ín;

ó ère, ó ń foríbalẹ̀ fún un.

16 Ìlàjì igi náà ni ó nínú iná;

lórí i rẹ̀ ni ó ti ń tọ́oúnjẹ rẹ̀,

ó dín ẹran rẹ̀ ó jẹ àjẹyó.

Ó tún ara rẹ̀ gbóná ó sọ ,

"Á à! Ara mi gbóná, mo iná."

17 Nínú èyí ó ni ó ti ṣe òrìṣà, ère rẹ̀;

ó foríbalẹ̀ fún un, ó sìn ín.

Ó gbàdúrà i, ó ,

"Gbà , ìwọ ni Ọlọ́run mi."

18 Wọn mọ nǹkan kan, nǹkan kan wọn;

a fi ìbòjú bo ojú wọn, wọn nǹkan kan;

bẹ́̀ ni àyà wọn sébọ́, wọn mọ nǹkan kan.

19 ẹni ó dúró láti ronú,

ẹni ó ìmọ̀ tàbí òye

láti sọ ,

"Ìlàjì rẹ̀ ni mo fi dáná;

mo tilẹ̀ ṣe àkàrà lórí èédú rẹ̀,

mo dín ẹran, mo jẹ ́.

Ǹjẹ́ ó yẹ n ṣe ohun ìríra kan

nínú èyí ó ṣẹ́?

Ǹjẹ́ èmi yóò ha foríbalẹ̀ fún ìtì igi?"

20 Ó ń jẹ eérú, ọkàn ẹlẹ́tàn ni ó ṣì í lọ́;

òun gba ara rẹ̀ , tàbí ó ,

"Ǹjẹ́ nǹkan ó lọ́wọ́ ̀tún mi yìí irọ́ kọ́?"

21 "Rántí àwọn nǹkan wọ̀nyí, ìwọ Jakọbu,

nítorí ìránṣẹ́ mi ni ìwọ, ìwọ Israẹli.

Èmi ti , ìránṣẹ́ mi ni ìwọ ṣe,

ìwọ Israẹli, Èmi yóò gbàgbé rẹ.

22 Èmi ti gbá gbogbo ìkùnà rẹ dànù i kurukuru,

àwọn ̀ṣẹ̀ rẹ ìrì òwúrọ̀.

Padà sọ́dọ̀ mi,

nítorí mo ti ́ padà."

23 Kọrin fáyọ̀, ̀yin ̀run, nítorí Olúwa ti ṣe èyí;

kígbe sókè, ìwọ ilẹ̀ ayé nísàlẹ̀.

orin, ̀yin òkè ńlá,

̀yin igbó àti gbogbo igi yín,

nítorí Olúwa ti ra Jakọbu padà,

ó ti fi ògo rẹ̀ hàn Israẹli.

A ó tún máa gbé Jerusalẹmu

24 "Ohun Olúwa nìyìí

Olùràpadà rẹ ó mọ ́

láti inú ìyá rẹ :

"Èmi ni Olúwa

ó ti ṣe ohun gbogbo

òun nìkan ti na àwọn ̀run

o tẹ́ ayé pẹrẹsẹ òun tìkára rẹ̀,

25 ta ni ó ba àmì àwọn wòlíì èké jẹ́

ó sọ àwọn aláfọ̀ṣẹ di òmùgọ̀,

ó dojú ìmọ̀ àwọn ọlọ́gbọ́n délẹ̀

ó sọ wọ́n di òmùgọ̀,

26 ẹni ó gbé ̀rọ̀ àwọn ìránṣẹ́ rẹ̀ jáde

ó àsọtẹ́lẹ̀ àwọn ìránṣẹ́ rẹ ìmúṣẹ,

"ẹni ó nípa ti Jerusalẹmu , A ó máa gbé inú rẹ̀,’

àti ti àwọn ìlú Juda, A ó tún kọ́,’

àti àwọn ahoro rẹ̀, Èmi yóò un bọ̀ sípò,

27 ta ni ó sọ fún omi jíjìn , Ìwọ gbẹ,

èmi yóò omi odò rẹ gbẹ,

28 ta ni ó sọ nípa Kirusi , Òun ni Olùṣọ́-àgùntàn mi

àti òun yóò ṣe ohun gbogbo mo fẹ́;

òun yóò sọ nípa Jerusalẹmu , "Jẹ́ a tún kọ́,"

àti nípa tẹmpili, "Jẹ́ a fi ìpìlẹ̀ rẹ̀ ilẹ̀." ’ "

Veja também

Publicidade
Bíblia Online Bíblia Online

Bíblia Online • Versão: 2026-06-28_14-13-17-