Pular para o conteúdo
Publicidade

1 Reis 19

20 Nígbà náà ni Eliṣa fi àwọn màlúù sílẹ̀, ó sáré tọ Elijah lẹ́yìn. Ó , "Èmi bẹ̀ ́, jẹ́ èmi lọ fi ẹnu ko baba àti ìyá mi ẹnu. Nígbà náà ni èmi yóò tọ̀ ́ lẹ́yìn."

Elijah dáhùn , "Padà sẹ́yìn, ni mo fi ṣe ́?"

21 Eliṣa fi í sílẹ̀, ó padà sẹ́yìn. Ó àjàgà màlúù rẹ, ó pa wọ́n. Ó fi ohun èlò àwọn màlúù náà bọ́ ẹran wọn, ó fi fún àwọn ènìyàn, wọ́n jẹ. Nígbà náà ni ó dìde láti tọ Elijah lẹ́yìn, ó ṣe ìránṣẹ́ fún un.

Veja também