Publicidade

1 Reis 3

5 Gibeoni, Olúwa fi ara han Solomoni lójú àlá òru, Ọlọ́run , "Béèrè fún ohunkóhun o ń fẹ́ èmi ó fi fún ."

6 Solomoni dáhùn , "O ti fi inú rere oore ńlá hàn ìránṣẹ́ rẹ, Dafidi baba mi, nítorí ó jẹ́ olóòtítọ́ àti olódodo àti ẹni ó ọkàn ìdúró ṣinṣin. Ìwọ tẹ̀síwájú nínú oore ńlá yìí fún un, ìwọ ti fún un ọmọkùnrin láti jókòó lórí ìtẹ́ rẹ gbogbo ọjọ́.

7 "Nísinsin yìí, Olúwa Ọlọ́run mi, o ti ìránṣẹ́ rẹ jẹ ọba ipò Dafidi baba mi. Ṣùgbọ́n ọmọ kékeré ni , èmi mọ jíjáde àti wíwọlé mi. 8 Ìránṣẹ́ rẹ nìyí láàrín àwọn ènìyàn o ti yàn, àwọn ènìyàn ńlá, wọ́n pọ̀ bẹ́̀ a wọ́n tàbí mọye wọn. 9 Nítorí náà fi ọkàn ìmòye fún ìránṣẹ́ rẹ láti le ṣàkóso àwọn ènìyàn rẹ àti láti mọ ìyàtọ̀ láàrín rere àti búburú. Nítorí ta ni ó ṣe àkóso àwọn ènìyàn ńlá rẹ yìí?"

10 Inú Olúwa dùn Solomoni béèrè nǹkan yìí. 11 Nígbà náà ni Ọlọ́run fún un , "Nítorí ìwọ ti béèrè fún èyí, í ṣe ̀gígùn tàbí ọrọ̀ fún ara rẹ, tàbí béèrè fún ikú àwọn ̀rẹ, ṣùgbọ́n fún òye láti mọ ẹjọ́ , 12 èmi yóò ṣe ohun ìwọ ti béèrè. Èmi yóò fún ọgbọ́n àti ọkàn ìmòye, bẹ́̀ fi ẹnìkan ó dàbí rẹ ṣáájú rẹ, bẹ́̀ ni ẹnìkan yóò dìde yóò dàbí rẹ lẹ́yìn rẹ.

Veja também

Bíblia Online Bíblia Online

Bíblia Online • Versão: 2026-07-04_23-13-58-