Publicidade

1 Reis 8

A gbé àpótí ̀inú tẹmpili

1 8.1-6: If 11.19. Nígbà náà ni Solomoni pe àwọn àgbàgbà Israẹli àti gbogbo àwọn olórí àwọn ̀àti àwọn olórí ìdílé àwọn ọmọ Israẹli jọ papọ̀, níwájú Solomoni ọba Jerusalẹmu, láti gbé àpótí ̀Olúwa láti ìlú Dafidi, ń ṣe Sioni. 2 Gbogbo àwọn ọkùnrin Israẹli pe ara wọn jọ sọ́dọ̀ Solomoni ọba àkókò àjọ ọdún oṣù Etanimu í ṣe oṣù keje.

3 Nígbà gbogbo àwọn àgbàgbà Israẹli , àwọn àlùfáà gbé àpótí ̀, 4 wọ́n gbé àpótí ̀Olúwa àti àgọ́ àjọ ènìyàn àti gbogbo ohun èlò mímọ́ ó nínú àgọ́. Àwọn àlùfáà àti àwọn ọmọ Lefi gbé wọn gòkè , 5 àti Solomoni ọba, àti gbogbo ìjọ ènìyàn ó péjọ ̀dọ̀ rẹ̀ pẹ̀rẹ̀ níwájú àpótí ̀, wọ́n ń fi ̀pọ̀lọpọ̀ àgùntàn àti màlúù a le mọ iye, àti a le ẹbọ.

6 Nígbà náà ni àwọn àlùfáà gbé àpótí ̀ti májẹ̀Olúwa ipò rẹ̀, ibi inú lọ́hùn ún ilé Olúwa, Ibi Mímọ́ Jùlọ, wọ́n gbé e abẹ́ ìyẹ́ àwọn kérúbù. 7 Àwọn kérúbù na ìyẹ́ wọn méjèèjì ibi àpótí ̀, wọ́n bo àpótí ̀náà, àti àwọn ̀rẹ̀ a fi ń gbé e. 8 Àwọn ̀yìí ga bẹ́̀ a fi le orí wọn láti Ibi Mímọ́ níwájú ibi a mímọ́, ṣùgbọ́n a wọn lóde Ibi Mímọ́, wọ́n níbẹ̀ títí di òní yìí. 9 ohun kankan nínú àpótí ̀ṣe wàláà òkúta méjì Mose ti fi ibẹ̀ Horebu, níbi Olúwa ti àwọn ọmọ Israẹli májẹ̀, lẹ́yìn ìgbà wọ́n jáde kúrò ilẹ̀ Ejibiti.

10 8.10,11: 2Ki 5.13,14; If 15.8. Nígbà àwọn àlùfáà jáde láti Ibi Mímọ́, àwọsánmọ̀ kún ilé Olúwa. 11 Àwọn àlùfáà le ṣiṣẹ́ wọn nítorí àwọsánmọ̀ náà, nítorí ògo Olúwa kún ilé náà.

12 8.12-50: 2Ki 6.1-39. Nígbà náà ni Solomoni , "Olúwa ti , òun yóò máa gbé inú òkùnkùn biribiri. 13 Nítòótọ́, èmi ti kọ́ ilé kan fún , ibi ìwọ yóò máa gbé títí láéláé."

14 Nígbà gbogbo ìjọ ènìyàn Israẹli dúró síbẹ̀, ọba ojú rẹ̀, ó bùkún fún wọn. 15 Nígbà náà ni ó ,

"Ìbùkún ni fún Olúwa, Ọlọ́run Israẹli, ẹni ó ti fi ọwọ́ ara rẹ̀ ìlérí ó fi ẹnu rẹ̀ sọ fún Dafidi baba mi ṣẹ. Nítorí ó , 16 Láti ọjọ́ èmi ti àwọn ènìyàn mi Israẹli jáde kúrò Ejibiti, èmi ì yan ìlú kan nínú gbogbo ̀Israẹli láti kọ́ ilé kan fún orúkọ mi láti níbẹ̀, ṣùgbọ́n èmi ti yan Dafidi láti ṣàkóso àwọn Israẹli ènìyàn mi.

17 "Dafidi baba mi i lọ́kàn láti kọ́ ilé kan fún orúkọ Olúwa Ọlọ́run Israẹli. 18 Ṣùgbọ́n Olúwa fún Dafidi baba mi , Nítorí ó ọkàn rẹ láti kọ́ ilé kan fún orúkọ mi, ó dára láti èyí ọkàn rẹ. 19 Ṣùgbọ́n, ìwọ kọ́ ni yóò kọ́ ilé náà, ṣùgbọ́n ọmọ rẹ, ó tinú ara rẹ àti ̀jẹ̀ rẹ jáde; òun ni yóò kọ́ ilé náà fún orúkọ mi.

20 "Olúwa ti pa ìlérí rẹ̀ ó ṣe mọ́, èmi ti rọ́Dafidi baba mi, mo jókòó lórí ìtẹ́ Israẹli báyìí, gẹ́gẹ́ Olúwa ti ṣèlérí, èmi kọ́ ilé kan fún orúkọ Olúwa, Ọlọ́run Israẹli. 21 Èmi ti pèsè ibìkan níbẹ̀ fún àpótí ̀, èyí í ṣe májẹ̀Olúwa ó ti àwọn baba wa , nígbà ó wọn jáde láti ilẹ̀ Ejibiti ."

Àdúrà Solomoni fún ìyàsímímọ́

22 Solomoni dúró níwájú pẹpẹ Olúwa, níwájú gbogbo ìjọ ènìyàn Israẹli, ó na ọwọ́ rẹ̀ méjèèjì sókè ̀run. 23 Ó ,

"Olúwa Ọlọ́run Israẹli, Ọlọ́run ó dàbí rẹ lókè ̀run tàbí ìsàlẹ̀ ilẹ̀ ìwọ ó pa májẹ̀àti àánú mọ́ pẹ̀àwọn ìránṣẹ́ rẹ ń fi gbogbo ọkàn wọn rìn níwájú rẹ. 24 O ti pa ìlérí rẹ mọ́ fún ìránṣẹ́ rẹ Dafidi baba mi; pẹ̀ẹnu rẹ ni ìwọ ṣe ìlérí, o u ṣẹ pẹ̀ọwọ́ rẹ, ó ti lónìí.

25 "Ǹjẹ́ báyìí Olúwa Ọlọ́run Israẹli, ìránṣẹ́ rẹ̀ Dafidi baba mi pa ohun ìwọ ti ṣe ìlérí fún un mọ́ , ìwọ yóò kùnà láti ènìyàn kan láti jókòó níwájú mi lórí ìtẹ́ Israẹli, kìkì àwọn ọmọ rẹ kíyèsi ohun wọ́n ń ṣe láti máa rìn níwájú mi ìwọ ti rìn. 26 Ǹjẹ́ báyìí, Ọlọ́run Israẹli, jẹ́ ̀rọ̀ rẹ o ti ṣe ìlérí fún ìránṣẹ́ rẹ̀ Dafidi baba mi ìmúṣẹ.

27 "Ṣùgbọ́n nítòótọ́, Ọlọ́run yóò máa gbé ayé ? ̀run àti ̀run àwọn ̀run le gbà ́. a sọ ilé yìí mo kọ́ fún ! 28 Síbẹ̀ ṣe ìfetísílẹ̀ àdúrà ìránṣẹ́ rẹ àti ̀bẹ̀ rẹ fún àánú, Olúwa Ọlọ́run mi. Gbọ́ ẹkún àti àdúrà ìránṣẹ́ rẹ̀ ń gbà níwájú rẹ lónìí. 29 Jẹ́ ojú rẹ ṣí ilé yìí òru àti ̀sán, ibí yìí ìwọ ti , orúkọ mi yóò níbẹ̀, nítorí ìwọ yóò gbọ́ àdúrà ìránṣẹ́ rẹ gbà ibí yìí. 30 Gbọ́ ̀bẹ̀ ìránṣẹ́ rẹ àti ti Israẹli, ènìyàn rẹ nígbà wọ́n gbàdúrà ibí yìí. Gbọ́ láti ̀run láti ibùgbé rẹ, àti nígbà o gbọ́, dáríjì.

31 "Nígbà ẹnìkan ṣẹ̀ ẹnìkejì rẹ̀, a fi e láti un búra, ìbúra náà iwájú pẹpẹ rẹ ilé yìí, 32 nígbà náà ni o gbọ́ láti ̀run, o ṣe. o ṣèdájọ́ láàrín àwọn ìránṣẹ́ rẹ, ènìyàn búburú lẹ́bi, o orí òun tìkára rẹ̀ ohun ó ti ṣe, olóòtítọ́ láre, a fi ẹsẹ̀ àìlẹ́bi rẹ̀ múlẹ̀.

33 "Nígbà àwọn ̀ṣẹ́gun Israẹli, ènìyàn rẹ, nítorí wọ́n ti ṣẹ̀ , wọ́n yípadà , wọ́n jẹ́wọ́ orúkọ rẹ, wọ́n gbàdúrà, wọ́n bẹ̀bẹ̀ lọ́dọ̀ rẹ nínú ilé yìí 34 nígbà náà ni o gbọ́ láti ̀run , o dárí ̀ṣẹ̀ Israẹli, ènìyàn rẹ̀ í, o wọn padà ilẹ̀ ìwọ ti fún àwọn baba wọn.

35 "Nígbà ̀run mọ́, òjò, nítorí àwọn ènìyàn rẹ ti ṣẹ̀ , wọ́n gbàdúrà ìhà ibí yìí, wọ́n jẹ́wọ́ orúkọ rẹ, wọ́n yípadà kúrò nínú ̀ṣẹ̀ wọn nítorí ìwọ ti pọ́n wọn lójú, 36 nígbà náà ni o gbọ́ láti ̀run , o dárí ̀ṣẹ̀ àwọn ìránṣẹ́ rẹ wọ́n, à Israẹli, ènìyàn rẹ. Kọ́ wọn ̀ó tọ́ láti máa rìn, o rọ òjò ilẹ̀ ìwọ ti fi fún ènìyàn rẹ fún ìní.

37 "Nígbà ìyàn tàbí àjàkálẹ̀-ààrùn ilẹ̀ náà, tàbí ìrẹ̀dànù tàbí ìmúwòdù, eṣú tàbí kòkòrò ń jẹ ni run, tàbí nígbà àwọn ̀wọ́n nínú àwọn ìlú wọn, irú ìpọ́njú tàbí ààrùnkárùn , 38 nígbà àdúrà tàbí ̀bẹ̀ ti ̀dọ̀ ẹnìkan láti ̀dọ̀ gbogbo Israẹli , olúkúlùkù mọ ìbànújẹ́ ọkàn rẹ̀, ó tẹ́ ọwọ́ rẹ̀ méjèèjì ìhà ilé yìí, 39 nígbà náà ni o gbọ́ láti ̀run , ibùgbé rẹ. Dáríjì, o ṣe olúkúlùkù ènìyàn gẹ́gẹ́ gbogbo ohun ó ti ṣe, níwọ̀n ìgbà ìwọ mọ ọkàn rẹ̀, nítorí ìwọ nìkan ṣoṣo ni ó mọ ọkàn gbogbo ènìyàn. 40 Nítorí wọn yóò bẹ̀rẹ gbogbo ọjọ́ wọn yóò ilẹ̀ ìwọ fi fún àwọn baba wa.

41 "ti àwọn àlejò í ṣe Israẹli ènìyàn rẹ, ṣùgbọ́n ó ti ilẹ̀ òkèèrè jáde nítorí orúkọ rẹ, 42 nítorí àwọn ènìyàn yóò gbọ́ orúkọ ńlá rẹ, àti ọwọ́ agbára rẹ, àti nínà apá rẹ, nígbà ó , ó gbàdúrà ìhà ilé yìí, 43 nígbà náà ni o gbọ́ láti ̀run , ibùgbé rẹ, o ṣe gbogbo èyí àlejò náà yóò béèrè lọ́wọ́ rẹ, gbogbo ènìyàn ayé mọ orúkọ rẹ, wọn ó máa bẹ̀rẹ, gẹ́gẹ́ Israẹli, ènìyàn rẹ ti ṣe, wọn ó le mọ̀ orúkọ rẹ ni a fi pe ilé yìí mo kọ́.

44 "Nígbà àwọn ènìyàn rẹ jáde lọ ogun àwọn ̀wọn, níbikíbi ìwọ rán wọn, nígbà wọ́n gbàdúrà Olúwa ìhà ìlú ìwọ ti yàn àti síhà ilé mo ti kọ́ fún orúkọ rẹ, 45 nígbà náà ni o gbọ́ àdúrà àti ̀bẹ̀ wọn láti ̀run, o ̀rọ̀ wọn dúró.

46 "Nígbà wọ́n ṣẹ̀ , nítorí ẹnìkan í ṣẹ̀, ìwọ bínú wọn, ìwọ fi wọ́n ̀lọ́wọ́, ó wọn ìgbèkùn lọ ilẹ̀ wọn, jíjìnnà tàbí nítòsí; 47 wọ́n ìyípadà ọkàn ilẹ̀ níbi a wọn ìgbèkùn lọ, wọ́n ronúpìwàdà, wọ́n bẹ̀bẹ̀ ilẹ̀ àwọn ó wọn ìgbèkùn lọ, , Àwa ti ṣẹ̀, àwa ti ṣe ohun tọ́, àwa ti ṣe búburú; 48 wọ́n fi gbogbo àyà àti gbogbo ọkàn wọn yípadà , ilẹ̀ àwọn ̀wọn, ó wọn ìgbèkùn lọ, wọ́n gbàdúrà ìhà ilẹ̀ wọn ìwọ ti fi fún àwọn baba wọn, ìlú ìwọ ti yàn, àti ilé èmi kọ́ fún orúkọ rẹ; 49 nígbà náà ni ìwọ ó gbọ́ àdúrà wọn àti ̀bẹ̀ wọn ̀run, ibùgbé rẹ, o ̀ràn wọn dúró. 50 o dáríjì àwọn ènìyàn rẹ, wọ́n ti dẹ́ṣẹ̀ ; dárí gbogbo ìrékọjá wọn wọ́n ṣe , o àwọn ó wọn ìgbèkùn lọ , wọn ó ṣàánú fún wọn; 51 nítorí ènìyàn rẹ àti ìní rẹ ni wọ́n, àwọn ẹni ìwọ ti ti Ejibiti jáde , láti inú irin ìléru.

52 "Jẹ́ ojú rẹ ṣí ̀bẹ̀ ìránṣẹ́ rẹ, àti ̀bẹ̀ àwọn ènìyàn rẹ Israẹli, o tẹ́sílẹ̀ wọn nígbà wọ́n kégbe . 53 Nítorí ìwọ ti wọ́n kúrò nínú gbogbo orílẹ̀-èdè ayé, láti máa jẹ́ ìní rẹ, ìwọ ti sọ láti ọwọ́ Mose ìránṣẹ́ rẹ, nígbà ìwọ Olúwa Olódùmarè, àwọn baba wa ti Ejibiti jáde ."

54 Nígbà Solomoni ti parí gbogbo àdúrà àti ̀bẹ̀ yìí Olúwa tán, ó dìde kúrò lórí eékún rẹ̀ níwájú pẹpẹ Olúwa níbi ó ti kúnlẹ̀ ó na ọwọ́ rẹ̀ òkè ̀run 55 Ó dìde dúró ó fi ohùn rara súre fún gbogbo ìjọ ènìyàn Israẹli ,

56 "Ìbùkún ni fún Olúwa ó ti fi ìsinmi fún Israẹli, ènìyàn rẹ̀ ó ti ṣèlérí. ̀rọ̀ rẹ̀ kan ó kùnà nínú gbogbo ìlérí rere ó ti ṣe láti ọwọ́ Mose ìránṣẹ́ rẹ̀ . 57 Olúwa Ọlọ́run wa ó pẹ̀wa ó ti pẹ̀àwọn baba wa; ó ṣe fi sílẹ̀ tàbí kọ̀ sílẹ̀. 58 ó fa ọkàn wa ̀dọ̀ ara rẹ̀, láti máa rìn nínú gbogbo ̀rẹ̀, àti láti pa òfin rẹ̀ mọ́, àti àṣẹ rẹ̀, àti ìlànà rẹ̀, ó ti pàṣẹ fún àwọn baba wa. 59 Àti ó jẹ́ àwọn ̀rọ̀ mi wọ̀nyí, mo ti gbà àdúrà níwájú Olúwa, ó nítòsí Olúwa Ọlọ́run wa ̀sán àti òru, ó ̀rọ̀ ìránṣẹ́ rẹ̀ dúró àti ̀rọ̀ Israẹli ènìyàn rẹ̀, gẹ́gẹ́ àìní wa ojoojúmọ́, 60 gbogbo ènìyàn ayé mọ̀ Olúwa òun ni Ọlọ́run, ẹlòmíràn. 61 Ṣùgbọ́n jẹ́ ọkàn yín pẹ̀Olúwa Ọlọ́run wa, láti máa rìn nínú àṣẹ rẹ̀ àti láti pa òfin rẹ̀ mọ́, i ti òní yìí."

Ìyàsímímọ́ ilé náà

62 8.62-66: 2Ki 7.4-10. Nígbà náà ni ọba àti gbogbo Israẹli ẹbọ níwájú Olúwa. 63 Solomoni ẹbọ àlàáfíà Olúwa: ẹgbẹ̀rún méjìlélógún (22,000) màlúù, àti ̀kẹ́ mẹ́(120,000) àgùntàn. Bẹ́̀ ni ọba àti gbogbo àwọn ọmọ Israẹli ya ilé Olúwa mímọ́.

64 ọjọ́ kan náà ni ọba ya àgbàlá àárín ń bẹ níwájú ilé Olúwa mímọ́, níbẹ̀ ni ó ẹbọ sísun àti ọrẹ oúnjẹ, àti ẹbọ àlàáfíà, nítorí pẹpẹ idẹ ń bẹ níwájú Olúwa kéré láti gba ẹbọ sísun, àti ọrẹ oúnjẹ, àti ọrẹ ẹbọ àlàáfíà.

65 Bẹ́̀ ni Solomoni ṣe àpéjọ nígbà náà, àti gbogbo Israẹli pẹ̀rẹ̀, àjọ ńlá ńlá ni, láti ìwọ Hamati títí odò Ejibiti. Wọ́n ṣàjọyọ̀ níwájú Olúwa Ọlọ́run wa ọjọ́ méje àti ọjọ́ méje i, ọjọ́ mẹ́rìnlá papọ̀. 66 ọjọ́ kẹjọ ó rán àwọn ènìyàn lọ. Wọ́n súre fún ọba, wọ́n lọ ilé wọn pẹ̀ayọ̀ àti inú dídùn fún gbogbo ohun rere Olúwa ti ṣe fún Dafidi ìránṣẹ́ rẹ̀, àti fún Israẹli ènìyàn rẹ̀.

Veja também

Bíblia Online Bíblia Online

Bíblia Online • Versão: 2026-07-04_23-13-58-