Pular para o conteúdo
Publicidade

1 Samuel 17

45 Dafidi fún Filistini , "Ìwọ dojú ìjà kọ pẹ̀idà, ̀kọ̀ àti ọfà, ṣùgbọ́n èmi ̀dọ̀ rẹ pẹ̀orúkọ Olúwa àwọn ọmọ-ogun, Ọlọ́run àwọn ọmọ-ogun Israẹli ìwọ gàn. 46 Lónìí yìí ni Olúwa yóò fi ́ mi lọ́wọ́, èmi yóò pa ́, èmi yóò orí rẹ. Lónìí èmi yóò fi òkú ogun Filistini fún ẹyẹ ojú ̀run àti fún ẹranko igbó, gbogbo ayé yóò mọ̀ Ọlọ́run Israẹli. 47 Gbogbo àwọn ó péjọ níbí ni yóò mọ̀ í ṣe nípa ̀kọ̀ tàbí idà ni Olúwa fi ń gbàlà; ogun náà ti Olúwa ni, yóò fi gbogbo yín ọwọ́ wa."

Veja também