Pular para o conteúdo
Publicidade

1 Samuel 17

Dafidi àti Goliati

1 Filistini àwọn ọmọ-ogun rẹ̀ jọ fún ogun Soko ti Juda. Wọ́n pàgọ́ Efesi-Damimu, láàrín Soko àti Aseka, 2 Saulu àti àwọn ọmọ Israẹli wọ́n ara wọ́n jọ pọ̀, wọ́n pàgọ́ àfonífojì Ela, wọ́n gbé ogun wọn sókè ̀láti pàdé àwọn Filistini. 3 Àwọn Filistini orí òkè kan àwọn ọmọ Israẹli orí òkè mìíràn, àfonífojì láàrín wọn.

4 ̀gágun a ń Goliati, ó jẹ́ ará Gati, ó láti ibùdó Filistini. Ó ga ìgbọ̀nwọ́ mẹ́àti ìnà ìka kan ìbú. 5 Ó àṣíborí idẹ orí rẹ̀, ó wọ ̀a fi idẹ pẹlẹbẹ ṣe, ìwọ̀n ̀náà jẹ́ ẹgbẹ̀rún márùn-ún (5,000) ṣékélì idẹ. 6 Òun wọ ìhámọ́ra idẹ ẹsẹ̀ rẹ̀ àti àpáta idẹ kan láàrín ̀yìn rẹ̀. 7 ̀̀kọ̀ rẹ̀ apásá ìhunṣọ, orí ̀kọ̀ rẹ̀ wọn ẹgbẹ̀ta (600) kilogiramu méje irin, ẹni ó ru asà ogun rẹ̀ lọ ṣáájú u rẹ̀.

8 Goliati dìde, ó kígbe ogun Israẹli , "Èéṣe ̀yin fi jáde , ṣe fún ogun? Ṣé èmi í ṣe Filistini ni, àbí ̀yin í ṣe ìránṣẹ́ Saulu? Yan ọkùnrin kan o jẹ́ ó sọ̀kalẹ̀ ̀dọ̀ mi. 9 òhun le ó pa , àwa yóò di ẹrú u yín, ṣùgbọ́n èmi ṣẹ́gun rẹ̀ mo pa á, ̀yin yóò di ẹrú u wa, ̀yin yóò máa sìn ." 10 Nígbà náà Filistini náà , "Èmi fi ìjà lọ ogun Israẹli òní! ọkùnrin kan jẹ́ a ara wa ." 11 Nígbà Saulu àti gbogbo àwọn ọmọ Israẹli gbọ́ ̀rọ̀ Filistini, ìdààmú wọn.

12 Nísinsin yìí Dafidi jẹ́ ọmọ ará Efrata kan orúkọ rẹ̀ ń jẹ́ Jese, ó láti Bẹtilẹhẹmu Juda, Jese ọmọ mẹ́jọ, àsìkò Saulu ó ti darúgbó ẹni ọdún púpọ̀. 13 Àwọn ọmọ Jese mẹ́tẹ̀̀ta ó ti dàgbà Saulu lọ ojú ogun, èyí àkọ́ni Eliabu, èyí èkejì ni Abinadabu, èyí ̀kẹta Ṣamma. 14 Dafidi ni ó kéré nínú wọn. Àwọn àgbà mẹ́tẹ̀̀ta tẹ̀Saulu, 15 ṣùgbọ́n Dafidi padà lẹ́yìn Saulu, láti máa tọ́àgùntàn baba rẹ̀ Bẹtilẹhẹmu.

16 Fún ogójì ọjọ́, Filistini síwájú àràárọ̀ àti ìrọ̀lẹ́ wọ́n fi ara wọn hàn.

17 Nísinsin yìí Jese fún ọmọ rẹ̀ Dafidi , "ìwọ̀n efa àti àgbàdo yíyan àti ìṣù àkàrà mẹ́wàá lọ fún àwọn ̀gbọ́n rẹ o súré lọ ibùdó o wọn. 18 o wàrà mẹ́wàá yìí lọ́wọ́ fún adarí ogun tiwọn. Wo àwọn ̀gbọ́n rẹ ṣe o padà fún mi àmì ìdánilójú láti ̀dọ̀ wọn. 19 Wọ́n pẹ̀Saulu àti gbogbo àwọn ọkùnrin Israẹli àfonífojì Ela, wọ́n àwọn Filistini ."

20 àárọ̀ kùtùkùtù Dafidi fi agbo ẹran rẹ̀ sílẹ̀ pẹ̀àwọn olùtọ́, ó di ẹrù, ó ̀rẹ̀ pọ̀n gẹ́gẹ́ Jese ti sọ fún un. Ó ibùdó àwọn ọmọ-ogun ti ń lọ láti dúró ipò wọn ojú ogun, wọ́n ìhó ogun. 21 Israẹli àti Filistini lọ ojú ìjà wọ́n da ojú ìjà kọ ara wọn. 22 Dafidi ẹrù rẹ̀ ti àwọn olùtọ́ohun èlò, ó sálọ ojú ogun ó àwọn ̀gbọ́n rẹ̀. 23 ó ṣe ń wọn sọ̀rọ̀, Goliati akíkanjú Filistini ó láti Gati bọ́ iwájú ojú ogun, ó kígbe fún ìpèníjà, Dafidi gbọ́. 24 Nígbà àwọn Israẹli ọkùnrin náà, gbogbo wọn fún un ìbẹ̀bojo.

25 Nígbà náà ni àwọn ọkùnrin Israẹli , "Ǹjẹ́ ̀yin i ọkùnrin yìí ṣe ń jáde ? Ó jáde láti pe Israẹli níjà. Ọba yóò fún ọkùnrin ó pa á ọrọ̀ púpọ̀. Yóò tún fi ọmọ rẹ̀ obìnrin fún un ìyàwó, yóò sọ ilé e baba rẹ̀ di òmìnira kúrò nínú sísan owó orí Israẹli."

26 Dafidi béèrè lọ́wọ́ ọkùnrin ó dúró ̀gbẹ́ rẹ̀ , "ni a yóò ṣe fún ọkùnrin náà ó pa Filistini yìí, ó ̀gàn kúrò lára Israẹli? Ta ni aláìkọlà Filistini ó jẹ́ yóò máa gan ogun Ọlọ́run alààyè?"

27 Wọ́n tún sọ fún un ohun wọ́n ti ń sọ, wọ́n , "Èyí ni ohun wọn yóò ṣe fún ọkùnrin ó pa á."

28 Nígbà Eliabu ̀gbọ́n Dafidi gbọ́ nígbà ó ń ọkùnrin yìí sọ̀rọ̀, ó bínú i, ó , "ni ó ìwọ fi sọ̀kalẹ̀ síbí? Àti ta ni ìwọ fi àwọn àgùntàn kékeré tókù ṣọ́ aginjù? Èmi mọ ìgbéraga rẹ, àti búburú ọkàn rẹ: ìwọ sọ̀kalẹ̀ nìkan láti wòran ogun."

29 Dafidi , "ni mo ṣe nísinsin yìí? Ǹjẹ́ mo sọ̀rọ̀ ?" 30 Ó yípadà ẹlòmíràn, ó ń sọ̀rọ̀ kan náà, ọkùnrin náà dáhùn ti ẹni ìṣáájú. 31 Àwọn ènìyàn gbọ́ ohun Dafidi sọ wọ́n sọ fún Saulu, Saulu ránṣẹ́ i.

32 Dafidi sọ fún Saulu , "ẹnikẹ́ni ṣe ba ọkàn jẹ́ nítorí Filistini yìí, ìránṣẹ́ rẹ yóò lọ láti a ."

33 Saulu fún Dafidi , "Ìwọ láti jáde lọ pàdé ogun Filistini yìí àti láti a ; ọmọdé ni ìwọ, òun ti ń jagun láti ìgbà èwe rẹ̀ ."

34 Ṣùgbọ́n Dafidi sọ fún Saulu , "Ọmọ ̀dọ̀ rẹ ti ń tọ́agbo àgùntàn baba rẹ̀. Nígbà kìnnìún tàbí àmọ̀tẹ́kùn láti gbé àgùntàn láti inú igbó. 35 Mo tẹ̀e, mo ú, mo gba àgùntàn náà kúrò lẹ́nu rẹ̀. Nígbà ó kọjú mi, mo fi irun rẹ̀ gbá a , mo ú mo pa á. 36 Ìránṣẹ́ rẹ ti pa kìnnìún àti àmọ̀tẹ́kùn, aláìkọlà Filistini yìí yóò jẹ́ ̀kan lára wọn, nítorí ó ti pe ogun Ọlọ́run alààyè ìjà. 37 Olúwa ó gbà kúrò lọ́wọ́ ìhàlẹ̀ kìnnìún àti ti ìhàlẹ̀ àmọ̀tẹ́kùn yóò gbà kúrò lọ́wọ́ Filistini yìí."

Saulu fún Dafidi , "Lọ Olúwa pẹ̀rẹ."

38 Saulu fi aṣọ àwọ̀tẹ́lẹ̀ rẹ̀ wọ Dafidi, ó wọ̀ ́ aṣọ ìhámọ́ra ogun, ó fi ìbòrí idẹ kan ó orí. 39 Dafidi si di idà rẹ̀ mọ́ àwọ̀tẹ́lẹ̀ rẹ̀ ó bẹ̀rẹ̀ rìn káàkiri nítorí mọ́ lára.

Ó sọ fún Saulu , "Èmi le wọ èyí lọ, mọ́ mi lára." Ó bọ́ wọn kúrò. 40 Nígbà náà, ó ̀rẹ̀ lọ́wọ́, ó ṣá òkúta dídán márùn-ún létí odò, ó wọn àpò olùṣọ́-àgùntàn ó lọ́wọ́ rẹ̀ pẹ̀kànnàkànnà, ó súnmọ́ Filistini náà.

41 Lákòókò yìí, Filistini pẹ̀ẹni ń gbé ìhámọ́ra ààbò níwájú rẹ̀, ó ń bọ̀ sọ́dọ̀ Dafidi. 42 Nígbà Filistini náà wo Dafidi láti òkè délẹ̀, ó i ọmọ kékeré kùnrin ni, ó pọ́n ó lẹ́lójú, ó kẹ́gàn an rẹ̀. 43 Ó fún Dafidi , "Ṣé ajá ni ni? o fi tọ̀ pẹ̀̀?" Filistini fi Dafidi pẹ̀Ọlọ́run rẹ̀. 44 Filistini náà Dafidi , "níbí, èmi yóò fi ẹran-ara rẹ fún àwọn ẹyẹ ojú ̀run jẹ àti fún àwọn ẹranko ó nínú igbó!"

45 Dafidi fún Filistini , "Ìwọ dojú ìjà kọ pẹ̀idà, ̀kọ̀ àti ọfà, ṣùgbọ́n èmi ̀dọ̀ rẹ pẹ̀orúkọ Olúwa àwọn ọmọ-ogun, Ọlọ́run àwọn ọmọ-ogun Israẹli ìwọ gàn. 46 Lónìí yìí ni Olúwa yóò fi ́ mi lọ́wọ́, èmi yóò pa ́, èmi yóò orí rẹ. Lónìí èmi yóò fi òkú ogun Filistini fún ẹyẹ ojú ̀run àti fún ẹranko igbó, gbogbo ayé yóò mọ̀ Ọlọ́run Israẹli. 47 Gbogbo àwọn ó péjọ níbí ni yóò mọ̀ í ṣe nípa ̀kọ̀ tàbí idà ni Olúwa fi ń gbàlà; ogun náà ti Olúwa ni, yóò fi gbogbo yín ọwọ́ wa."

48 Filistini ṣe súnmọ́ iwájú láti pàdé e rẹ̀. Dafidi yára sáré òun náà láti pàdé e rẹ̀. 49 Dafidi ti ọwọ́ àpò rẹ̀, ó òkúta jáde ó í, ó ú ̀kọ́kán iwájú orí Filistini. Òkúta náà wọ̀ ́ níwájú orí, ó ṣubú ó dojúbolẹ̀ orí ilẹ̀.

50 Dafidi yọ ayọ̀ ìṣẹ́gun lórí Filistini pẹ̀kànnàkànnà àti òkúta, láìsí idà ọwọ́ rẹ̀, ó lu Filistini, ó pa á.

51 Dafidi sáré ó dúró lórí rẹ̀. Ó idà Filistini, ó á yọ nínú àkọ̀ rẹ̀. Lẹ́yìn ìgbà ó ti pa á tan, ó orí rẹ̀ pẹ̀idà.

Nígbà àwọn ará Filistini i akọni wọn ti , wọ́n yípadà wọ́n sálọ. 52 Nígbà náà, àwọn ọkùnrin Israẹli àti ti Juda súnmọ́ iwájú pẹ̀ariwo, wọ́n lépa àwọn ará Filistini ẹnu ibodè Gati àti títí ẹnu ibodè Ekroni. Àwọn ó káàkiri ̀gbẹ́ ̀Ṣaaraimu àti títí ̀Gati àti Ekroni. 53 Nígbà àwọn ọmọ Israẹli padà láti máa àwọn ará Filistini, wọ́n ba ibùdó wọn jẹ́.

54 Dafidi orí Filistini ó gbé e Jerusalẹmu, ó àwọn ohun ìjà Filistini sínú àgọ́ tirẹ̀.

55 Saulu ti wo Dafidi ó ṣe ń jáde lọ pàdé Filistini, ó fún Abneri, olórí àwọn ológun rẹ̀ , "Abneri, ọmọ ta ni ọmọdékùnrin yìí?"

Abneri dáhùn pe, "ọkàn rẹ̀ ti ń bẹ ààyè, ọba èmi mọ̀."

56 Ọba , "Wádìí ọmọ ẹni ọmọdékùnrin náà ń ṣe."

57 Kété ó láti ibi ó ti lọ pa Filistini, Abneri u síwájú Saulu, orí Filistini ọwọ́ Dafidi.

58 Saulu béèrè , "Ọmọdékùnrin, ọmọ ta ni ́?"

Dafidi dáhùn , "Èmi ni ọmọ ìránṣẹ́ rẹ Jese ti Bẹtilẹhẹmu."

Veja também