Publicidade

1 Samuel 6

Àpótí ̀Olúwa padà Israẹli

1 Nígbà àpótí ̀Olúwa ti agbègbè Filistini fún oṣù méje, 2 àwọn ará Filistini pe àwọn àlùfáà, àti àwọn alásọtẹ́lẹ̀, wọ́n sọ , "ni a ṣe pẹ̀àpótí ̀Olúwa? Sọ fún wa àwa yóò ti a padà ààyè rẹ̀."

3 Wọ́n dáhùn , "àpótí ̀Ọlọ́run ti àwọn ọmọ Israẹli padà, ṣe a padà òfìfo, ṣùgbọ́n ó ti ó , fún un ẹbọ ̀bi. Nígbà náà ni a ó un yín láradá, ̀yin yóò mọ ìdí ọwọ́ rẹ̀ fi ì kúrò lára yín."

4 Àwọn ará Filistini béèrè , "Irú ẹbọ ̀bi wo ni a fi fún un?"

Wọ́n dáhùn, "Wúrà oníkókó márùn-ún àti eku ̀lírí wúrà márùn-ún, gẹ́gẹ́ iye àwọn aláṣẹ Filistini, nítorí àjàkálẹ̀-ààrùn kan náà ni ó kọlù yín àti olórí yín. 5 Mọ àwòrán ààrùn oníkókó àti ti eku ̀lírí yin ó ń ba orílẹ̀-èdè náà jẹ́ o bu ọlá fún Ọlọ́run Israẹli. Bóyá yóò gbé ọwọ́ rẹ̀ kúrò lára yín, lára ọlọ́run yín àti lára ilẹ̀ yín. 6 ni ó fi ń ọkàn yín le gẹ́gẹ́ àwọn ará Ejibiti àti Farao ti ṣe? Nígbà ó fi ọwọ́ líle wọn, ṣé wọn rán àwọn ọmọ Israẹli jáde wọn ó lọ ̀wọn?

7 "Nísinsin yìí pèsè kẹ̀kẹ́ ẹrù tuntun sílẹ̀, pẹ̀màlúù méjì ó ti fi ọmú fún ọmọ, èyí a ì gba àjàgà ọrùn , so ó mọ́ kẹ̀kẹ́ náà, ọmọ wọn kúrò lọ́dọ̀ wọn ilé láti so. 8 gbé àpótí ̀Olúwa orí kẹ̀kẹ́ ẹrù àti ̀yin àwọn ohun èlò wúrà ̀yin fi fún un gẹ́gẹ́ ti ẹbọ ̀bi inú àpótí ̀gbẹ́ rẹ̀, ̀yin ó rán an lọ, 9 ṣùgbọ́n máa ṣọ́ . ó ń lọ ilẹ̀ rẹ̀, ìlú rẹ̀, níhà Beti-Ṣemeṣi. Nígbà náà ni Olúwa àjálù ńlá yìí wa. Ṣùgbọ́n ṣe bẹ́̀ nígbà náà ni a mọ̀ í ṣe ọwọ́ rẹ̀ ni ó kọlù , ṣùgbọ́n ó bẹ́̀ ni."

10 Nígbà náà ni wọ́n ṣe èyí. Wọ́n abo màlúù méjì, ń fi ọmú fún ọmọ, wọn mọ́ ara, wọ́n é ni ilé kẹ̀kẹ́ ẹrù, wọn so àwọn ọmọ wọn mọ́lẹ̀ ni ilé. 11 Wọ́n gbé àpótí ̀Olúwa orí kẹ̀kẹ́ ̀gbẹ́ rẹ̀ ni àpótí eku ̀lírí wúrà àti àwòrán ààrùn oníkókó níbẹ̀. 12 Nígbà náà; àwọn màlúù lọ tààrà ìhà Beti-Ṣemeṣi, wọ́n ń lọ tààrà, wọ́n ń dún wọ́n ti ń lọ. Wọn ̀tún tàbí òsì. Àwọn aláṣẹ Filistini tẹ̀wọn títí ibodè Beti-Ṣemeṣi.

13 Nísinsin yìí, àwọn ará Beti-Ṣemeṣi ń kórè jéró wọn pẹ̀tẹ́lẹ̀, nígbà wọ́n wo òkè wọ́n àpótí ̀Olúwa, wọ́n yọ̀ níwájú rẹ̀. 14 Kẹ̀kẹ́ ẹrù pápá Joṣua ti Beti-Ṣemeṣi, níbẹ̀ ni ó ti dúró ̀àpáta ńlá kan. Àwọn ènìyàn igi ara kẹ̀kẹ́ ẹrù wẹ́wẹ́ wọ́n fi àwọn màlúù náà ẹbọ sísun Olúwa. 15 Àwọn ará Lefi gbé àpótí ̀Olúwa ìsàlẹ̀ pẹ̀àpótí ohun èlò wúrà níbẹ̀, wọ́n gbé wọn ka orí àpáta ńlá náà. ọjọ́ náà, àwọn ará Beti-Ṣemeṣi ẹbọ sísun, wọ́n ṣe ìrúbọ Olúwa. 16 Àwọn aláṣẹ Filistini márààrún gbogbo èyí, wọ́n padà ọjọ́ náà Ekroni.

17 Èyí ni kókó wúrà àwọn Filistini fún Olúwa gẹ́gẹ́ ẹbọ ̀bi ̀kọ̀̀kan fún Aṣdodu, ̀kan ti Gasa, ̀kan ti Aṣkeloni, ̀kan ti Gati, ̀kan ti Ekroni. 18 Wúrà eku ̀lírí jẹ́ iye ìlú àwọn aláṣẹ Filistini márààrún ti , ìlú olódi pẹ̀ìletò wọn. Àpáta ńlá náà, lórí èyí a gbé àpótí ̀Olúwa jẹ́ ̀títí di òní oko Joṣua ará Beti-Ṣemeṣi.

19 Ṣùgbọ́n Ọlọ́run kọlu díẹ̀ lára àwọn ọkùnrin Beti-Ṣemeṣi, ó pa àádọ́rin wọn, nítorí wọ́n ti wo inú àpótí ̀Olúwa. Àwọn ènìyàn ṣọ̀fọ̀ nítorí àjálù ńlá Olúwa fi ̀pọ̀ wọn . 20 Àwọn ọkùnrin ará Beti-Ṣemeṣi béèrè , "Ta ni ó le è dúró iwájú Olúwa Ọlọ́run mímọ́ yìí? ̀dọ̀ ta ni àpótí ̀Olúwa yóò gbà gòkè lọ láti ibí yìí?"

21 Nígbà náà, wọ́n rán àwọn ìránṣẹ́ àwọn ènìyàn Kiriati-Jearimu , "Àwọn Filistini ti àpótí ̀Olúwa padà. sọ̀kalẹ̀ , gbé e gòkè lọ ̀dọ̀ yín."

Veja também

Bíblia Online Bíblia Online

Bíblia Online • Versão: 2026-07-04_23-13-58-