Publicidade

Deuteronômio 10

Wàláà òfin i ti ìṣáájú

1 Nígbà náà ni Olúwa fún mi , "Gbé wàláà òkúta méjì i ti àkọ́kọ́ o gòkè tọ̀ . o tún fi igi kan àpótí kan. 2 Èmi yóò kọ ̀rọ̀ ó lára wàláà àkọ́kọ́ ìwọ fọ́, sára wàláà wọ̀nyí. Ìwọ yóò fi wọ́n sínú àpótí náà."

3 Mo kan àpótí náà pẹ̀igi kasia, mo gbẹ́ wàláà òkúta méjì náà jáde i ti ìṣáájú. Mo gòkè lọ pẹ̀wàláà méjèèjì lọ́wọ́ . 4 Olúwa tún ohun ó ti kọ tẹ́lẹ̀ kọ sórí wàláà wọ̀nyí. Àwọn òfin mẹ́wẹ̀̀ó ti sọ fún un yín lórí òkè, láàrín iná, ọjọ́ ìpéjọpọ̀. Olúwa fi wọ́n fún mi. 5 Mo sọ̀kalẹ̀ láti orí òkè náà, mo ki àwọn wàláà òkúta náà sínú àpótí mo ti kàn, Olúwa ti pàṣẹ fún mi, wọ́n níbẹ̀ di ìsinsin yìí.

6 (Àwọn ará Israẹli gbéra láti kànga àwọn ará Jaakani Mosera. Níbí ni Aaroni , a sin ín, Eleasari ọmọ rẹ̀ rọ́rẹ̀ i àlùfáà. 7 Láti ibẹ̀ ni wọ́n ti rìn lọ Gudgoda, títí Jotbata, ilẹ̀ o kún fún odò ó ń sàn. 8 ìgbà yìí ni Olúwa yan àwọn ̀Lefi láti máa ru àpótí ̀Olúwa, láti máa dúró níwájú Olúwa láti ṣe iṣẹ́ ìránṣẹ́, àti láti fi orúkọ Olúwa súre wọ́n ti ń ṣe títí di òní yìí. 9 Ìdí nìyí àwọn ̀Lefi fi ìpín tàbí ogún kan láàrín àwọn arákùnrin wọn. Olúwa ni ogún wọn gẹ́gẹ́ Olúwa Ọlọ́run ti sọ fún un yín.)

10 Mo tún dúró orí òkè náà fún ogójì ̀sán àti ogójì òru, mo ti ṣe ìgbà àkọ́kọ́, Olúwa gbọ́ tèmi àkókò yìí bákan náà. í ṣe ìfẹ́ rẹ̀ láti run yín. 11 Olúwa sọ fún mi , "Lọ darí àwọn ènìyàn wọ̀nyí ̀wọn, wọn à wọ ilẹ̀ náà, wọn gba ilẹ̀ mo ti búra fún àwọn baba wọn láti fún wọn."

bẹ̀Olúwa

12 Nísinsin yìí ìwọ Israẹli, kín ni ohun Olúwa Ọlọ́run rẹ béèrè lọ́wọ́ rẹ? ṣe ìwọ bẹ̀Olúwa Ọlọ́run rẹ àti láti máa rìn gbogbo ̀rẹ̀, láti fẹ́ràn rẹ̀, láti fi gbogbo ọkàn rẹ sin Olúwa Ọlọ́run rẹ ọkàn àti àyà rẹ, 13 àti láti máa kíyèsi àṣẹ àti ìlànà Olúwa mo ń fún lónìí, fún ìre ara à rẹ.

14 ó tilẹ̀ jẹ́ Olúwa Ọlọ́run yín ni ó ni ̀run àní àwọn ̀run ga ju ayé àti ohun gbogbo ó nínú rẹ̀. 15 Síbẹ̀ Olúwa tún fi ìfẹ́ rẹ̀ hàn fún àwọn baba ńlá a yín, Ó fẹ́ wọn Ó yan ̀yin ọmọ wọn láti borí gbogbo orílẹ̀-èdè títí di òní. 16 kọ ọkàn yín ilà, ṣe jẹ́ olórí kunkun mọ́ láti òní lọ. 17 10.17: Ap 10.34; Ga 2.6; If 17.14; 19.16.Torí Olúwa Ọlọ́run yín, ni Ọlọ́run àwọn ọlọ́run àti Olúwa àwọn olúwa. Ọlọ́run alágbára, ó tóbi ó lẹ́, í ṣe ojúsàájú í í gba àbẹ̀tẹ́lẹ̀. 18 Ó máa ń gbẹjọ́ aláìní baba àti opó , Ó fẹ́ràn àjèjì, Òun fi aṣọ àti oúnjẹ fún wọn. 19 10.19: El 22.21; 23.9; Le 19.34.gbọdọ̀ fẹ́ràn àwọn àjèjì, torí ̀yin pẹ̀ti jẹ́ àjèjì Ejibiti. 20 bẹ̀Olúwa Ọlọ́run yín, máa sìn ín. dìímú ṣinṣin, búra orúkọ rẹ̀. 21 Òun ni ìyìn in yín, Òun ni Ọlọ́run yín, ó ṣe àwọn iṣẹ́ ìyanu ńlá àti ohun ̀, fojú ara yín . 22 10.22: Ap 7.14.Àádọ́rin péré ni àwọn baba ńlá a yín ó sọ̀kalẹ̀ lọ Ejibiti, ṣùgbọ́n Olúwa Ọlọ́run yín ti un yín pọ̀ i iye àwọn ìràwọ̀ ojú ̀run.

Veja também

Bíblia Online Bíblia Online

Bíblia Online • Versão: 2026-07-05_19-25-13-