Publicidade

Deuteronômio 15

Ọdún ìyọ̀ǹda àti ìdáríjì

1 òpin ọdún méje méje, ̀yin gbọdọ̀ máa yọ̀ǹda àwọn gbèsè. 2 Báyìí ni máa ṣe é. Gbogbo ẹni wọ́n jẹ gbèsè gbọdọ̀ fojú fo gbèsè ó ti ará Israẹli ènìyàn rẹ̀. gbọdọ̀ béèrè ohun náà, lọ́dọ̀ ará Israẹli ènìyàn rẹ̀ tàbí lọ́dọ̀ arákùnrin rẹ̀: nítorí a ti kéde àkókò Olúwa láti fojú fo gbèsè. 3 béèrè ìsanpadà lọ́dọ̀ àjèjì. Ṣùgbọ́n fa igi gbèsè yówù jẹ́ arákùnrin yín jẹ yín. 4 Ṣùgbọ́n ẹni yóò tọ́ nínú yín, nítorí Olúwa Ọlọ́run yín yóò bùkún un yín lọ́pọ̀lọ́pọ̀ nínú ilẹ̀ náà ó ń un yín lọ láti gbà ìní yín. 5 Kìkì gbọ́rọ̀ àṣẹ Olúwa Ọlọ́run yín kíyèsára láti máa rìn nínú gbogbo àṣẹ wọ̀nyí, èmi ń pa fún un yín lónìí. 6 Nítorí Olúwa Ọlọ́run yín yóò bùkún un yín ó ti ṣèlérí, ̀yin yóò máa ̀pọ̀lọpọ̀ orílẹ̀-èdè yóò tọrọ. ó ṣàkóso ̀pọ̀lọpọ̀ orílẹ̀-èdè, ṣùgbọ́n orílẹ̀-èdè yóò jẹ ọba e yín lórí.

7 tálákà kan láàrín àwọn arákùnrin yín èyíkéyìí àwọn ìlú, ilẹ̀ náà Olúwa yín yóò fún un yín. ṣe ṣe àìláàánú, bẹ́̀ ni ṣe háwọ́ arákùnrin yín ó jẹ́ tálákà. 8 Ṣùgbọ́n lawọ́ fi tọkàntọkàn wọn ohun wọ́n nílò. 9 ṣọ́ra èrò búburú kan ṣe nínú àyà rẹ , "Ọdún keje í ṣe ọdún ìyọ̀ǹda gbèsè ti súnmọ́," nípa bẹ́̀, ojú rẹ a burú arákùnrin rẹ tálákà, ìwọ fun nǹkan, o fun nǹkan kan. Òun a si kígbe pe Olúwa nítorí rẹ, a si di ̀ṣẹ̀ fún . 10 Fún un tọkàntọkàn, láìsí ìkùnsínú, nítorí èyí, Olúwa Ọlọ́run rẹ yóò bùkún fún nínú iṣẹ́ ọwọ́ rẹ, àti gbogbo ìdáwọ́rẹ. 11 A fẹ́ tálákà ilẹ̀ náà ìgbà gbogbo, mo pàṣẹ fún un yín láti lawọ́ àwọn arákùnrin yín, àwọn tálákà àti àwọn aláìní, ilẹ̀ yín.

Ìdásílẹ̀ àwọn ẹrú

12 Heberu ara yín kan, yálà ọkùnrin tàbí obìnrin ta ara rẹ̀ fún , ó sìn ́ fún ọdún mẹ́. ọdún keje, jẹ́ ó di òmìnira. 13 Nígbà ó a sílẹ̀ ṣe jẹ́ ó lọ lọ́wọ́ òfo. 14 Fi tọkàntọkàn fún un láti inú agbo ewúrẹ́ rẹ, ilẹ̀ ìpakà rẹ, àti ibi ìfúntí rẹ. Fún un gẹ́gẹ́ Olúwa Ọlọ́run rẹ ti bùkún fún . 15 rántí ti fi ìgbà kan jẹ́ ẹrú Ejibiti, Olúwa Ọlọ́run yín yín padà, ìdí nìyí mo fi pa àṣẹ yìí fún un yín lónìí.

16 Ṣùgbọ́n ìránṣẹ́ rẹ sọ fún , "Èmi fẹ́ fi ́ sílẹ̀," nítorí ó fẹ́ràn ìwọ àti ìdílé rẹ, ó tẹ́ lọ́rùn, 17 ìwọ ó ìlu kan lu etí rẹ̀ mọ́ ara ìlẹ̀kùn, yóò di ẹrú rẹ láéláé. Bẹ́̀ náà ni o ṣe ìránṣẹ́ ẹrúbìnrin rẹ.

18 ṣe á ohun ìnira láti ẹrú rẹ sílẹ̀, nítorí ìsìnrú rẹ̀ fún , ọdún mẹ́náà ìlọ́po méjì iṣẹ́ alágbàṣe, Olúwa Ọlọ́run rẹ yóò bùkún fún nínú gbogbo ìdáwọ́rẹ.

Àkọ́àwọn ẹran ̀sìn

19 Gbogbo àkọ́o jẹ́ akọ nínú agbo màlúù rẹ ni o sọ́tọ̀ fún Olúwa, àti nínú agbo ewúrẹ́ bákan náà. ṣe fi àkọ́màlúù yín ṣiṣẹ́ rárá. ṣe rẹ́ irun àkọ́àgùntàn rẹ pẹ̀. 20 ọdọọdún ni ìwọ àti ìdílé rẹ máa jẹ ́ níwájú Olúwa Ọlọ́run yín níbi Òun yóò yàn. 21 ẹran ̀sìn kan àbùkù: bóyá ó yarọ, tàbí fọ́, tàbí ó èyíkéyìí àbùkù burú. gbọdọ̀ fi ẹbọ Olúwa Ọlọ́run yín. 22 jẹ ́ ìlú u yín. Àti ẹni a mímọ́ àti aláìmọ́ ni ó jẹ ́ ìgbà a ń jẹ èsúró tàbí àgbọ̀nrín. 23 Ṣùgbọ́n ̀yin gbọdọ̀ jẹ ̀jẹ̀, á síta omi.

Veja também

Publicidade
Bíblia Online Bíblia Online

Bíblia Online • Versão: 2026-06-29_22-07-56-