Publicidade

Deuteronômio 15

Ọdún ìyọ̀ǹda àti ìdáríjì

1 òpin ọdún méje méje, ̀yin gbọdọ̀ máa yọ̀ǹda àwọn gbèsè. 2 Báyìí ni máa ṣe é. Gbogbo ẹni wọ́n jẹ gbèsè gbọdọ̀ fojú fo gbèsè ó ti ará Israẹli ènìyàn rẹ̀. gbọdọ̀ béèrè ohun náà, lọ́dọ̀ ará Israẹli ènìyàn rẹ̀ tàbí lọ́dọ̀ arákùnrin rẹ̀: nítorí a ti kéde àkókò Olúwa láti fojú fo gbèsè. 3 béèrè ìsanpadà lọ́dọ̀ àjèjì. Ṣùgbọ́n fa igi gbèsè yówù jẹ́ arákùnrin yín jẹ yín. 4 Ṣùgbọ́n ẹni yóò tọ́ nínú yín, nítorí Olúwa Ọlọ́run yín yóò bùkún un yín lọ́pọ̀lọ́pọ̀ nínú ilẹ̀ náà ó ń un yín lọ láti gbà ìní yín. 5 Kìkì gbọ́rọ̀ àṣẹ Olúwa Ọlọ́run yín kíyèsára láti máa rìn nínú gbogbo àṣẹ wọ̀nyí, èmi ń pa fún un yín lónìí. 6 Nítorí Olúwa Ọlọ́run yín yóò bùkún un yín ó ti ṣèlérí, ̀yin yóò máa ̀pọ̀lọpọ̀ orílẹ̀-èdè yóò tọrọ. ó ṣàkóso ̀pọ̀lọpọ̀ orílẹ̀-èdè, ṣùgbọ́n orílẹ̀-èdè yóò jẹ ọba e yín lórí.

7 15.7,8: Le 25.35. tálákà kan láàrín àwọn arákùnrin yín èyíkéyìí àwọn ìlú, ilẹ̀ náà Olúwa yín yóò fún un yín. ṣe ṣe àìláàánú, bẹ́̀ ni ṣe háwọ́ arákùnrin yín ó jẹ́ tálákà. 8 Ṣùgbọ́n lawọ́ fi tọkàntọkàn wọn ohun wọ́n nílò. 9 ṣọ́ra èrò búburú kan ṣe nínú àyà rẹ , "Ọdún keje í ṣe ọdún ìyọ̀ǹda gbèsè ti súnmọ́," nípa bẹ́̀, ojú rẹ a burú arákùnrin rẹ tálákà, ìwọ fun nǹkan, o fun nǹkan kan. Òun a si kígbe pe Olúwa nítorí rẹ, a si di ̀ṣẹ̀ fún . 10 Fún un tọkàntọkàn, láìsí ìkùnsínú, nítorí èyí, Olúwa Ọlọ́run rẹ yóò bùkún fún nínú iṣẹ́ ọwọ́ rẹ, àti gbogbo ìdáwọ́rẹ. 11 A fẹ́ tálákà ilẹ̀ náà ìgbà gbogbo, mo pàṣẹ fún un yín láti lawọ́ àwọn arákùnrin yín, àwọn tálákà àti àwọn aláìní, ilẹ̀ yín.

Ìdásílẹ̀ àwọn ẹrú

12 15.12-18: El 21.2-11; Le 25.39-46. Heberu ara yín kan, yálà ọkùnrin tàbí obìnrin ta ara rẹ̀ fún , ó sìn ́ fún ọdún mẹ́. ọdún keje, jẹ́ ó di òmìnira. 13 Nígbà ó a sílẹ̀ ṣe jẹ́ ó lọ lọ́wọ́ òfo. 14 Fi tọkàntọkàn fún un láti inú agbo ewúrẹ́ rẹ, ilẹ̀ ìpakà rẹ, àti ibi ìfúntí rẹ. Fún un gẹ́gẹ́ Olúwa Ọlọ́run rẹ ti bùkún fún . 15 rántí ti fi ìgbà kan jẹ́ ẹrú Ejibiti, Olúwa Ọlọ́run yín yín padà, ìdí nìyí mo fi pa àṣẹ yìí fún un yín lónìí.

16 Ṣùgbọ́n ìránṣẹ́ rẹ sọ fún , "Èmi fẹ́ fi ́ sílẹ̀," nítorí ó fẹ́ràn ìwọ àti ìdílé rẹ, ó tẹ́ lọ́rùn, 17 ìwọ ó ìlu kan lu etí rẹ̀ mọ́ ara ìlẹ̀kùn, yóò di ẹrú rẹ láéláé. Bẹ́̀ náà ni o ṣe ìránṣẹ́ ẹrúbìnrin rẹ.

18 ṣe á ohun ìnira láti ẹrú rẹ sílẹ̀, nítorí ìsìnrú rẹ̀ fún , ọdún mẹ́náà ìlọ́po méjì iṣẹ́ alágbàṣe, Olúwa Ọlọ́run rẹ yóò bùkún fún nínú gbogbo ìdáwọ́rẹ.

Àkọ́àwọn ẹran ̀sìn

19 15.19-23: El 13.11,12; 22.30; 34.19; Nu 18.17,18. Gbogbo àkọ́o jẹ́ akọ nínú agbo màlúù rẹ ni o sọ́tọ̀ fún Olúwa, àti nínú agbo ewúrẹ́ bákan náà. ṣe fi àkọ́màlúù yín ṣiṣẹ́ rárá. ṣe rẹ́ irun àkọ́àgùntàn rẹ pẹ̀. 20 ọdọọdún ni ìwọ àti ìdílé rẹ máa jẹ ́ níwájú Olúwa Ọlọ́run yín níbi Òun yóò yàn. 21 ẹran ̀sìn kan àbùkù: bóyá ó yarọ, tàbí fọ́, tàbí ó èyíkéyìí àbùkù burú. gbọdọ̀ fi ẹbọ Olúwa Ọlọ́run yín. 22 jẹ ́ ìlú u yín. Àti ẹni a mímọ́ àti aláìmọ́ ni ó jẹ ́ ìgbà a ń jẹ èsúró tàbí àgbọ̀nrín. 23 15.23: Gẹ 9.4; Le 7.26,27; 17.10-14; 19.26; De 12.16,23.Ṣùgbọ́n ̀yin gbọdọ̀ jẹ ̀jẹ̀, á síta omi.

Veja também

Bíblia Online Bíblia Online

Bíblia Online • Versão: 2026-07-04_21-26-40-