Publicidade

Deuteronômio 28

Ìbùkún fún ìgbọ́ràn

1 ìwọ gbọ́rọ̀ Olúwa Ọlọ́run rẹ kíkún o kíyèsára láti tẹ̀gbogbo ohun ó pàṣẹ mo fi fún lónìí, Olúwa Ọlọ́run rẹ yóò gbé lékè ju gbogbo orílẹ̀-èdè ayé lọ. 2 Gbogbo ìbùkún yìí yóò sórí rẹ yóò máa lọ o gbọ́rọ̀ Olúwa Ọlọ́run rẹ.

3 Ìbùkún ni fún ni ìlú, ìbùkún ni fún oko.

4 Ìbùkún ni fún ọmọ inú rẹ, àti èso ilẹ̀ rẹ, àti irú ohun ̀sìn rẹ àti ìbísí i màlúù rẹ àti ọmọ àgùntàn rẹ.

5 Ìbùkún ni fún agbọ̀n rẹ àti fún ọpọ́n ipò ìyẹ̀fun rẹ.

6 Ìbùkún ni fún nígbà ìwọ wọlé, ìbùkún ni fún nígbà ìwọ jáde.

7 Olúwa yóò gbà fún gbogbo ̀ó dìde yóò ṣubú níwájú rẹ. Wọn yóò tọ̀ ́ ̀kan ṣùgbọ́n wọn yóò fún ̀méje.

8 Olúwa yóò rán ìbùkún àti ohun gbogbo o dáwọ́ rẹ . Olúwa Ọlọ́run rẹ yóò bùkún un fún nínú ilẹ̀ ó ń fi fún .

9 Olúwa yóò fi ́ múlẹ̀ ènìyàn mímọ́, ó ti ṣe ìlérí fún lórí ìbúra, o pa àṣẹ Olúwa Ọlọ́run rẹ mọ́ o ń rìn ̀rẹ̀. 10 Nígbà náà ni gbogbo ènìyàn ó ayé yóò i a ́ orúkọ Olúwa, wọn yóò bẹ̀rẹ. 11 Olúwa yóò fi àlàáfíà fún ̀kúnrẹ́rẹ́, fún ọmọ inú rẹ, irú ohun ̀sìn rẹ àti àwọn èso ilẹ̀ rẹ ilẹ̀ ó ti búra fún àwọn baba ńlá rẹ láti fún .

12 Olúwa yóò ṣí ̀run sílẹ̀, ìṣúra rere rẹ̀ fún , láti rọ òjò sórí ilẹ̀ rẹ àsìkò rẹ àti láti bùkún gbogbo iṣẹ́ ọwọ́ ̀ rẹ. Ìwọ yóò ̀pọ̀lọpọ̀ orílẹ̀-èdè ṣùgbọ́n ìwọ í lọ́wọ́ ẹnìkankan. 13 Olúwa yóò fi ́ ṣe orí, ìwọ yóò jẹ́ ìrù. o fi etí sílẹ̀ àṣẹ Olúwa Ọlọ́run rẹ mo fi fún o máa rọra tẹ̀wọn, ìwọ yóò máa lókè, bẹ́̀ ni ìwọ yóò ìsàlẹ̀ láé. 14 ṣe sọ́tùn tàbí sósì kúrò, nínú èyíkéyìí àwọn àṣẹ mo fi fún òní yìí, o ṣe tẹ̀àwọn ọlọ́run mìíràn láti máa sìn wọ́n.

Ègún fún àìgbọ́ràn

15 Ṣùgbọ́n o gbọ́ ti Olúwa Ọlọ́run rẹ o rọra máa tẹ̀gbogbo àṣẹ àti òfin rẹ̀ ń fún lónìí, gbogbo ègún yìí yóò sórí rẹ yóò máa lọ.

16 Ègún ni fún ìlú, ègún ni fún oko.

17 Ègún ni fún agbọ̀n rẹ àti ọpọ́n ìpo-fúláwà rẹ.

18 Ègún ni fún ọmọ inú rẹ, àti èso ilẹ̀ rẹ, ìbísí màlúù rẹ àti ọmọ àgùntàn rẹ.

19 Ègún ni fún nígbà o wọlé ègún ni fún nígbà ìwọ jáde.

20 Olúwa yóò rán ègún sórí rẹ, rúdurùdu àti ìfibú nínú gbogbo ohun o dáwọ́ rẹ , títí ìwọ yóò fi parun àti ìparun lójijì nítorí búburú o ti ṣe kíkọ̀ mi sílẹ̀. 21 Olúwa yóò fi àjàkálẹ̀-ààrùn títí yóò fi pa ́ run kúrò ilẹ̀ ò ń wọ̀ lọ láti . 22 Olúwa yóò kọlù ́ pẹ̀ààrùn ìgbẹ́, pẹ̀ibà àti àìsàn wíwú, pẹ̀ìjóni ńlá àti idà, pẹ̀ìrẹ̀dànù àti ìmúwòdù yóò yọ ́ lẹ́nu títí ìwọ yóò fi parun. 23 Ojú ̀run ó lórí rẹ yóò jẹ́ idẹ, ilẹ̀ ń bẹ níṣàlẹ̀ rẹ yóò jẹ́ irin. 24 Olúwa yóò òjò ilẹ̀ rẹ eruku àti ̀; láti ̀run ni yóò ti máa sọ̀kalẹ̀ , títí ìwọ yóò fi run.

25 Olúwa yóò fi ́ gégùn ún láti ṣubú níwájú àwọn ̀rẹ. Ìwọ yóò tọ̀ wọ́n ̀kan ṣùgbọ́n ìwọ yóò fún wọn ̀méje, ìwọ yóò padà di ohun ìbẹ̀fún gbogbo ìjọba lórí ayé. 26 Òkú rẹ yóò jẹ́ oúnjẹ fún gbogbo ẹyẹ ojú ̀run àti fún ẹranko ayé, àti ẹnikẹ́ni yóò wọn kúrò. 27 Olúwa yóò pẹ̀oówo, Ejibiti àti pẹ̀kókó, ojú egbò kíkẹ̀ àti ìhúnra. 28 Olúwa yóò pẹ̀ìsínwín, ojú fífọ́ àti rúdurùdu àyà. 29 ̀sán gangan ìwọ yóò fi ọwọ́ tálẹ̀ kiri ọkùnrin afọ́nínú òkùnkùn ìwọ yóò ṣe àṣeyọrí nínú ohun gbogbo o ń ṣe, ojoojúmọ́ ni wọn yóò máa ni ́ lára àti ́ olè, í ẹnìkan láti gbà ́.

30 Ìwọ yóò gba ògo láti fẹ́ obìnrin kan ṣùgbọ́n ẹlòmíràn yóò gbà á yóò tẹ́ ́ ògo. Ìwọ yóò kọ́ ilé, ṣùgbọ́n ìwọ yóò gbé ibẹ̀. Ìwọ yóò gbin ọgbà àjàrà, ṣùgbọ́n ìwọ tilẹ̀ gbádùn èso rẹ. 31 Màlúù rẹ yóò di pípa níwájú rẹ, ṣùgbọ́n ìwọ yóò jẹ nǹkan kan nínú rẹ̀. Kẹ́tẹ́kẹ́tẹ́ rẹ yóò di mímú pẹ̀agbára kúrò lọ́dọ̀ rẹ, a yóò da padà. Àgùntàn rẹ yóò di mímú fún àwọn ̀rẹ, ẹnìkankan gbà á. 32 Àwọn ọmọkùnrin àti ọmọbìnrin rẹ yóò di mímú fún àwọn orílẹ̀-èdè mìíràn, ìwọ yóò fi ojú rẹ ṣọ́dúró wọ́n láti ọjọ́ ọjọ́, ìwọ yóò jẹ́ aláìlágbára láti gbé ọwọ́. 33 Èso ilẹ̀ rẹ àti gbogbo iṣẹ́ làálàá rẹ ni orílẹ̀-èdè mìíràn ìwọ mọ̀ yóò jẹ, ìwọ yóò jẹ́ kìkì ẹni ìnilára àti ẹni ìtẹ̀mọ́lẹ̀. 34 Ìran ojú rẹ yóò , yóò sọ ́ di òmùgọ̀. 35 Olúwa yóò lu eékún àti ẹsẹ̀ rẹ pẹ̀oówo dídùn le san tán láti àtẹ̀méjèèjì rẹ lọ òkè orí rẹ.

36 Olúwa yóò àti ọba ó yàn lórí rẹ lọ orílẹ̀-èdè ìwọ mọ̀ tàbí ti àwọn baba rẹ mọ̀. Ibẹ̀ ni ìwọ̀ yóò sin ọlọ́run mìíràn, ọlọ́run igi àti òkúta. 37 Ìwọ yóò di ẹni ìyanu, àti ẹni òwe, àti ẹni ìfisọ̀rọ̀ sọ nínú gbogbo orílẹ̀-èdè Olúwa yóò darí rẹ .

38 Ìwọ yóò gbin irúgbìn púpọ̀ ṣùgbọ́n ìwọ yóò kórè kékeré, nítorí eṣú yóò jẹ ́ run. 39 Ìwọ yóò gbin ọgbà àjàrà púpọ̀ ìwọ yóò ro wọ́n ṣùgbọ́n wáìnì náà tàbí àwọn èso jọ, nítorí kòkòrò yóò jẹ wọ́n run. 40 Ìwọ yóò igi olifi jákèjádò ilẹ̀ rẹ ṣùgbọ́n ìwọ lo òróró náà, nítorí olifi náà yóò rẹ̀ dànù. 41 Ìwọ yóò àwọn ọmọkùnrin àti ọmọbìnrin ṣùgbọ́n ìwọ nípa wọ́n mọ́, nítorí wọn yóò lọ ìgbèkùn. 42 ̀wọ́ eṣú yóò gba gbogbo àwọn igi rẹ àti àwọn èso ilẹ̀ rẹ.

43 Àjèjì ń gbé láàrín rẹ yóò gbé sókè gíga ́ lọ, ṣùgbọ́n ìwọ yóò máa di ìrẹ̀sílẹ̀. 44 Yóò ́, ṣùgbọ́n o yóò á, òun ni yóò jẹ́ orí, ìwọ yóò jẹ́ ìrù.

45 Gbogbo ègún yìí yóò sórí rẹ, wọn yóò wọn yóò títí ìwọ yóò fi parun, nítorí ìwọ gbọ́rọ̀ Olúwa Ọlọ́run rẹ, ìwọ kíyèsi àṣẹ àti òfin ó fi fún . 46 Wọn yóò jẹ́ àmì àti ìyanu fún àti fún irú-ọmọ rẹ títí láé. 47 Nítorí ìwọ sin Olúwa Ọlọ́run rẹ ayọ̀ àti inú dídùn àkókò àlàáfíà. 48 Nítorí náà nínú ebi àti òǹgbẹ, nínú ìhòhò àti àìní búburú, ìwọ yóò sin àwọn ̀à rẹ Olúwa rán . Yóò fi àjàgà irin bọ̀ ́ ọrùn, títí yóò fi run ́.

49 Olúwa yóò àwọn orílẹ̀-èdè láti ̀jíjìn, òpin ayé, idì ti ń bẹ́ láti orí òkè sílẹ̀, orílẹ̀-èdè ìwọ gbọ́ èdè wọn. 50 Orílẹ̀-èdè ó rorò ojúrere fún àgbà tàbí àánú fún ọmọdé. 51 Wọn yóò jẹ ohun ̀sìn rẹ run àti àwọn èso ilẹ̀ rẹ títí ìwọ yóò fi parun. Wọn yóò fi hóró irúgbìn kan fún , wáìnì tuntun tàbí òróró, tàbí agbo ẹran màlúù rẹ kankan tàbí ̀wọ́ ẹran àgùntàn rẹ títí ìwọ yóò fi run. 52 Wọn yóò gbógun ti gbogbo ìlú rẹ títí odi ìdáàbòbò gíga yẹn ìwọ gbẹ́kẹ̀yóò fi lulẹ̀. Wọn yóò gbógun ti gbogbo ìlú rẹ jákèjádò ilẹ̀ Olúwa Ọlọ́run rẹ ń fún .

53 Ìwọ ó jẹ èso ọmọ inú rẹ̀, ẹran-ara àwọn ọmọ rẹ ọkùnrin àti ti àwọn ọmọ rẹ obìnrin Olúwa Ọlọ́run ti fi fún ; nínú ìdótì náà àti nínú ìhámọ́ náà àwọn ̀rẹ yóò mọ́. 54 Ọkùnrin àwọ̀ rẹ̀ tutù nínú yín, ó ṣe ẹlẹgẹ́, ojú rẹ̀ yóò korò arákùnrin rẹ̀ àti aya oókan àyà rẹ̀, àti ìyókù ọmọ rẹ̀ òun jẹ . 55 Bẹ́̀ ni yóò fún ẹnikẹ́ni nínú ẹran-ara àwọn ọmọ rẹ̀ ó ń jẹ, nítorí ohun kan ó sílẹ̀ fún un nínú ìdótì náà àti ìhámọ́, àwọn ̀yóò fi mọ́ ibodè rẹ gbogbo. 56 Obìnrin àwọ̀ rẹ̀ tutù nínú yín, ó ṣe ẹlẹgẹ́, jẹ́ dáṣà láti fi àtẹ́lẹsẹ̀ rẹ̀ kan ilẹ̀ nítorí ìkẹ́ra àti ìwà ẹlẹgẹ́, ojú u rẹ̀ yóò korò ọkọ oókan àyà rẹ̀, àti ọmọ rẹ̀ ọkùnrin, àti ọmọ rẹ̀ obìnrin, 57 àti ọmọ rẹ̀ ó ti agbede-méjì ẹsẹ̀ rẹ̀ jáde, àti àwọn ọmọ rẹ̀ yóò . Nítorí òun ó jẹ wọ́n ìkọ̀kọ̀, nítorí àìní ohunkóhun nínú ìdótì àti ìhámọ́ náà, àwọn ̀yóò fi mọ́ ibodè rẹ.

58 ìwọ rọra tẹ̀gbogbo àwọn ̀rọ̀ òfin yìí, a kọ sínú ìwé yìí, ìwọ bu ọlá fún ògo yìí àti orúkọ dáradára: orúkọ Olúwa Ọlọ́run rẹ, 59 Olúwa yóò sọ ìyọnu rẹ di ìyanu, àti ìyọnu irú-ọmọ ̀ rẹ, àní àwọn ìyọnu ńlá èyí yóò pẹ́, àti ààrùn búburú èyí yóò pẹ́. 60 Olúwa yóò gbogbo ààrùn Ejibiti ó ̀́ padà , wọn yóò lẹ̀ mọ́ . 61 Olúwa yóò tún onírúurú àìsàn àti ìpọ́njú a kọ sínú ìwé òfin yìí sórí rẹ, títí ìwọ yóò fi run. 62 Ìwọ ó dàbí àìmoye ìràwọ̀ ojú ̀run yóò ṣẹ́ku kékeré níye, nítorí o ṣe ìgbọ́ràn Olúwa Ọlọ́run rẹ. 63 Gẹ́gẹ́ ó ti dùn mọ́ Olúwa nínú láti ṣe rere àti láti pọ̀ si iye, bẹ́̀ ni yóò dùn mọ́ nínú láti ́ ṣubú ó pa ́ run. Ìwọ yóò di fífà tu kúrò lórí ilẹ̀ ò ń wọ̀ lọ láti .

64 Nígbà náà ni Olúwa yóò fọ́n láàrín gbogbo orílẹ̀-èdè, láti òpin kan ayé òmíràn. Níbẹ̀ ni ìwọ yóò ti sin ọlọ́run mìíràn: ọlọ́run igi àti ti òkúta. Èyí ìwọ àti àwọn baba rẹ mọ̀. 65 Ìwọ yóò sinmi láàrín àwọn orílẹ̀-èdè náà, ibi ìsinmi fún àtẹ́lẹsẹ̀ rẹ. Níbẹ̀ ni Olúwa yóò ti fún ọkàn ìnàngà, àárẹ̀ ojú, àti àìnírètí àyà. 66 Ìwọ yóò gbé ìdádúró ṣinṣin, kún fún ìbẹ̀rùbojo lọ́sàn án àti lóru, bẹ́̀ kọ́ láé ni ìwọ yóò i àrídájú wíwà láyé rẹ. 67 Ìwọ yóò òwúrọ̀ , "ó tilẹ̀ jẹ́ ìrọ̀lẹ́ nìkan ni!" Nítorí ̀yóò gba ọkàn rẹ àti ìran ojú rẹ yóò máa . 68 Olúwa yóò rán padà nínú ọkọ̀ Ejibiti ìrìnàjò mo ìwọ yóò lọ mọ́. Níbẹ̀ ni ìwọ yóò tún fi ara rẹ fún àwọn ̀à rẹ gẹ́gẹ́ ẹrúkùnrin àti ẹrúbìnrin, ṣùgbọ́n ẹni yóò ́.

Veja também

Publicidade
Bíblia Online Bíblia Online

Bíblia Online • Versão: 2026-06-29_22-07-56-