Pular para o conteúdo
Publicidade

Deuteronômio 30

Àlàáfíà lẹ́yìn ìyípadà Ọlọ́run

1 Nígbà gbogbo ìbùkún àti ègún wọ̀nyí mo ti gbé kalẹ̀ síwájú u yín sórí i yín àti o wọn àyà rẹ níbikíbi Olúwa Ọlọ́run rẹ láàrín àwọn orílẹ̀-èdè, 2 àti nígbà ìwọ àti àwọn ọmọ rẹ yípadà Olúwa Ọlọ́run rẹ o gbọ́rọ̀ pẹ̀gbogbo àyà rẹ àti gbogbo ọkàn rẹ gẹ́gẹ́ gbogbo ohun mo ti paláṣẹ fún un yín lónìí. 3 Nígbà náà ni Olúwa Ọlọ́run rẹ yóò ohun ìní rẹ bọ̀ sípò yóò ṣàánú fún , yóò tún ṣà yín jọ láti gbogbo orílẹ̀-èdè níbi ó ti fọ́n yín . 4 30.4: Mt 24.31; Mk 13.27.ó tilẹ̀ jẹ́ ó ti ẹni rẹ kan ilẹ̀ ó jìnnà lábẹ́ ̀run, láti ibẹ̀ Olúwa Ọlọ́run rẹ yóò ṣà yín jọ yóò tún u yín padà. 5 Yóò ilẹ̀ ó jẹ́ ti àwọn baba yín, ìwọ yóò ìní níbẹ̀. Olúwa yóò àlàáfíà kíkún, yóò pọ̀ i ju àwọn baba yín lọ. 6 Olúwa Ọlọ́run rẹ yóò kọ ọkàn rẹ ilà àti ọkàn àwọn ọmọ yín, nítorí o fẹ́ pẹ̀gbogbo àyà rẹ pẹ̀gbogbo ọkàn rẹ, àti ayé rẹ. 7 Olúwa Ọlọ́run rẹ yóò gbogbo ègún yín sórí àwọn ̀à rẹ wọ́n kórìíra àti wọ́n ṣe inúnibíni rẹ. 8 Ìwọ yóò tún gbọ́rọ̀ Olúwa àti tẹ̀gbogbo àṣẹ rẹ̀ ń fún lónìí. 9 Nígbà náà ni Olúwa Ọlọ́run rẹ yóò ṣe rere nínú gbogbo iṣẹ́ ọwọ́ ̀ rẹ, àti nínú gbogbo ọmọ inú rẹ, agbo ẹran ̀sìn rẹ àti èso ilẹ̀ rẹ. Olúwa yóò tún inú dídùn sínú rẹ yóò ṣe déédé, gẹ́gẹ́ ó ti fi inú dídùn sínú àwọn baba rẹ. 10 o gbọ́ ti Olúwa Ọlọ́run rẹ o pa òfin rẹ̀ mọ́ àti àṣẹ a kọ sínú ìwé òfin yìí o yípadà Olúwa Ọlọ́run rẹ pẹ̀gbogbo àyà rẹ àti pẹ̀gbogbo ọkàn rẹ.

Ìfifún ìyè tàbí ikú

11 Nítorí àṣẹ yìí mo pa fún lónìí, ṣòro fún , bẹ́̀ ni kọjá agbára rẹ. 12 30.12,13: Ro 10.6,7.̀run, ìwọ fi , "Ta ni yóò gòkè lọ ̀run fún wa, yóò wa fún wa, àwa gbọ́, a le ṣe é?" 13 Bẹ́̀ ni ìhà kejì Òkun, ìwọ ìbá fi , "Ta ni yóò rékọjá òkun lọ fún wa, yóò un fún wa, àwa gbọ́ , a si le ṣe é?" 14 30.14: Ro 10.8.í ṣe bẹ́̀, ̀rọ̀ náà súnmọ́ tòsí rẹ, ó ẹnu rẹ àti ọkàn rẹ ìwọ máa ṣe é.

15 ó mo gbé kalẹ̀ síwájú u yín lónìí, ìyè àti àlàáfíà, ikú àti ìparun. 16 èyí mo pàṣẹ fún òní láti máa fẹ́ Olúwa Ọlọ́run rẹ, láti máa rìn ̀rẹ̀ àti láti máa pa àṣẹ rẹ̀, àti ìlànà rẹ̀, àti ìdájọ́ rẹ̀ mọ́, ìwọ ó , ó máa i, Olúwa Ọlọ́run si fún ilẹ̀ náà, ibi ìwọ ń lọ láti gbà á.

17 Ṣùgbọ́n ọkàn an yín padà ìwọ ṣe ìgbọ́ràn, àti o , lọ láti foríbalẹ̀ fún ọlọ́run mìíràn àti sìn wọ́n, 18 èmi ń sọ fún un yín lónìí yìí ìwọ yóò parun láìsí àní àní. O í gbé pẹ́ ilẹ̀ ìwọ ń kọjá Jordani láti gbà àti láti .

19 Èmi pe ̀run àti ilẹ̀ láti jẹ́rìí yín òní , èmi fi ìyè àti ikú, ìbùkún àti ègún síwájú rẹ: nítorí náà yan ìyè, ìwọ ó , ìwọ àti irú-ọmọ rẹ, 20 ìwọ ó le máa fẹ́ Olúwa Ọlọ́run rẹ, fetísílẹ̀ ohùn un rẹ̀, o dúró ṣinṣin nínú rẹ̀. Nítorí Olúwa ni ìyè rẹ, yóò fún ọdún púpọ̀ ilẹ̀ ó ti búra láti fi fún àwọn baba rẹ Abrahamu, Isaaki àti Jakọbu.

Veja também