Publicidade

Deuteronômio 4

Mose pàṣẹ ìgbọ́ràn

1 Gbọ́ Israẹli, gbọ́ òfin àti ìlànà èmi yóò kọ́ yín. tẹ̀wọn ba à , ba à lọ láti gba ilẹ̀ Olúwa Ọlọ́run àwọn baba yín yóò fi fún un yín. 2 ṣe fi kún àwọn ohun mo pàṣẹ fún un yín, gbọdọ̀ yọ kúrò nínú wọn, ṣùgbọ́n pa òfin Olúwa Ọlọ́run yín mo fún un yín mọ́.

3 ti fi ojú ara yín ohun Olúwa ṣe Baali-Peori. Olúwa Ọlọ́run yín run gbogbo àwọn ó tẹ̀òrìṣà Baali-Peori kúrò àárín yín. 4 Ṣùgbọ́n gbogbo ̀yin gbẹ́kẹ̀Olúwa Ọlọ́run láìyẹsẹ̀ ni láààyè lónìí.

5 kíyèsi i, mo ti kọ́ yín àwọn òfin àti àṣẹ Olúwa Ọlọ́run mi ti pàṣẹ fún mi, ba à le tẹ̀wọn ilẹ̀ náà ń lọ láti ìní. 6 máa kíyèsi wọn dáradára. Èyí ni yóò fi ọgbọ́n àti òye yín han àwọn orílẹ̀-èdè. Àwọn wọn yóò gbọ́ nípa àwọn ìlànà wọ̀nyí, wọn yóò máa , "Dájúdájú, orílẹ̀-èdè ńlá yìí kún fún ọgbọ́n àti òye." 7 Orílẹ̀-èdè olókìkí wo ni ọlọ́run wọn tún súnmọ́ wọn, Olúwa Ọlọ́run wa ti súnmọ́ wa nígbàkígbà a ń é? 8 Orílẹ̀-èdè wo tún le lókìkí láti àwọn ìlànà òdodo, àti òfin gẹ́gẹ́ àwọn òfin wọ̀nyí mo ń gbé kalẹ̀ fún un yín lónìí.

9 Kìkì i kíyèsára, ṣọ́ra a yín gidigidi ba à gbàgbé àwọn ohun ojú yín ti , wọn ṣe kúrò lóókan àyà yín níwọ̀n ìgbà láààyè. máa fi wọ́n kọ́ àwọn ọmọ yín àti àwọn ọmọ wọn ń bọ̀ lẹ́yìn wọn. 10 rántí ọjọ́ dúró níwájú Olúwa Ọlọ́run yín Horebu, nígbà ó fún mi , "àwọn ènìyàn wọ̀nyí jọ síwájú mi láti gbọ́ ̀rọ̀ mi, wọ́n kọ́ láti máa bu ọlá náà fún mi gbogbo ìgbà wọ́n gbé lórí ilẹ̀ náà, wọ́n le è fi wọ́n kọ́ àwọn ọmọ wọn." 11 ̀yin súnmọ́ tòsí, dúró ẹsẹ̀ òkè náà, òkè náà ń jóná agbede-méjì ọrun, pẹ̀òkùnkùn, àti àwọsánmọ̀, àti òkùnkùn biribiri. 12 Olúwa yín sọ̀rọ̀ láti àárín iná náà . gbọ́ àwọn ìró ohùn, ṣùgbọ́n ẹnikẹ́ni, ohùn nìkan ni gbọ́. 13 Ó sọ àwọn májẹ̀rẹ̀ fún un yín àní àwọn òfin mẹ́wẹ̀̀ó pàṣẹ fún un yín láti máa tẹ̀, ó kọ wọ́n sórí wàláà òkúta méjì. 14 Olúwa pàṣẹ fún mi nígbà náà láti kọ yín ìlànà àti ìdájọ, ̀yin ó máa ṣe wọ́n ilẹ̀ náà, ibi ̀yin ń lọ láti gbà á.

Èèwọ̀ ni ìbọ̀rìṣà jẹ́

15 kíyèsára gidigidi, torí , ìrísí ohunkóhun ọjọ́ Olúwa yín sọ̀rọ̀ Horebu láti àárín iná . Torí náà ṣọ́ra yín gidigidi, 16 ma ba à ba ara yín jẹ́ nípa ṣíṣe ère fún ara yín, àní ère lóríṣìíríṣìí yálà èyí ó ìrísí ọkùnrin tàbí obìnrin, 17 tàbí ti ẹranko orí ilẹ̀, tàbí ti ẹyẹ ń òfúrufú, 18 tàbí ti àwòrán onírúurú ̀ń lórí ilẹ̀, tàbí ti ẹja nínú omi. 19 wòkè oòrùn, òṣùpá àti àwọn ìràwọ̀: àwọn ohun a ṣe lọ́jọ̀ sójú ̀run, ṣe jẹ́ wọ́n tàn yín jẹ bi ̀yin yóò foríbalẹ̀ fún wọn, àti láti máa sin ohun Olúwa Ọlọ́run yín fún gbogbo orílẹ̀-èdè lábẹ́ ̀run. 20 Olúwa Ọlọ́run yín ti ̀yin jáde kúrò nínú iná ìléru ńlá, àní Ejibiti, láti jẹ́ ènìyàn ìní i rẹ̀, ̀yin ti jẹ́ báyìí.

21 Inú Olúwa ru mi nítorí yín, ó ti búra èmi yóò la Jordani kọjá, èmi yóò wọ ilẹ̀ rere Olúwa Ọlọ́run fi fún un yín, ìní yín. 22 Èmi yóò ilẹ̀ yìí, èmi yóò la Jordani kọjá, ṣùgbọ́n ̀yin ti fẹ́ rékọjá òdìkejì odò láti gba ilẹ̀ rere náà. 23 ṣọ́ra, ṣe gbàgbé májẹ̀Olúwa Ọlọ́run yín ó ti a yín . ṣe ṣe ère ìrísí ohunkóhun fún ara yín, èèwọ̀ ni Olúwa Ọlọ́run yín á . 24 Torí iná ajónirun ni Olúwa Ọlọ́run yín, Ọlọ́run owú ni.

25 Lẹ́yìn ìgbà ti àwọn ọmọ àti àwọn ọmọ ọmọ, ti gbé ilẹ̀ yìí pẹ́, ba ara yín jẹ́ nípa ṣíṣe irú ère yówù jẹ́, ṣe búburú lójú Olúwa Ọlọ́run yín, un bínú. 26 Mo pe ̀run àti ayé láti jẹ́rìí takò yín lónìí, kíákíá ni ó parun ilẹ̀ náà ń la Jordani kọjá lọ láti gbà. pẹ́ ilẹ̀ náà, ṣùgbọ́n ̀yin yóò run pátápátá. 27 Olúwa yóò fọ́n yín àárín àwọn ènìyàn náà, àwọn díẹ̀ nínú yín ni yóò láàrín orílẹ̀-èdè Olúwa yóò fọ́n yín . 28 ó máa sin ọlọ́run á fi ọwọ́ ènìyàn ṣe: wọ́n fi igi àti òkúta ṣe, èyí le ríran, gbọ́rọ̀, jẹun tàbí gbọ́ òórùn. 29 ̀yin Olúwa Ọlọ́run yín láti bẹ̀ ́, ó ri i, a, pẹ̀gbogbo ọkàn yín àti gbogbo àyà a yín. 30 nínú wàhálà, gbogbo nǹkan wọ̀nyí ṣẹlẹ̀ yín, láìpẹ́ ó tún padà tọ Olúwa Ọlọ́run yín , ó gbọ́ tirẹ̀. 31 Nítorí Olúwa Ọlọ́run yín aláàánú ni, gbàgbé tàbí pa yín rẹ́ tàbí gbàgbé májẹ̀pẹ̀àwọn baba ńlá yín, èyí ó fi ìdí rẹ̀ múlẹ̀ nípa ìbúra.

Olúwa ni Ọlọ́run

32 béèrè báyìí nípa ti àwọn ọjọ́ ìgbàanì ṣáájú a i yín, láti ìgbà Ọlọ́run ti ènìyàn sórí ilẹ̀ ayé. béèrè láti igun ̀run kan èkejì. Ǹjẹ́ irú nǹkan olókìkí báyìí: ti ṣẹlẹ̀ ? Ǹjẹ́ a ti gbọ́ irú u rẹ̀ ? 33 Ǹjẹ́ àwọn ènìyàn mìíràn ì gbọ́ ohùn Ọlọ́run , ó sọ̀rọ̀ jáde láti inú iná, gẹ́gẹ́ ̀yin ti gbọ́ ? 34 Ǹjẹ́ Ọlọ́run kan ti gbìyànjú àti orílẹ̀-èdè kan jáde kúrò nínú òmíràn fúnra rẹ̀ , nípa ìdánwò, nípa iṣẹ́ àmì, àti iṣẹ́ ìyanu nípa ogun, tàbí nípa ọwọ́ agbára tàbí nína apá, àti nípa ̀ńlá: gẹ́gẹ́ gbogbo èyí Olúwa Ọlọ́run yín ṣe fún un yín Ejibiti ojú ̀yin tìkára yín?

35 A fi gbogbo nǹkan wọ̀nyí hàn yín a gbà Olúwa ni Ọlọ́run. ẹlòmíràn lẹ́yìn rẹ̀. 36 Ó jẹ́ gbọ́ ohùn rẹ̀ láti ̀run , láti kọ́ yín. ayé, ó fi iná ńlá rẹ̀ hàn yín, gbọ́ ohùn rẹ̀ láti àárín iná , 37 torí ó fẹ́ràn àwọn baba ńlá yín, ó yan àwọn ọmọ wọn ipò lẹ́yìn wọn. Nípa ìwà láààyè àti nípa agbára ńlá rẹ̀ ni ó fi un yín kúrò Ejibiti. 38 Láti àwọn orílẹ̀-èdè ó tóbi ó lágbára níwájú yín; láti le è un yín ilẹ̀ wọn jogún rẹ̀ ó ti lónìí.

39 gbà fi sọ́kàn lónìí Olúwa ni Ọlọ́run lókè ̀run lọ́hùn ún àti ilẹ̀ ìsàlẹ̀ níhìn-ín. òmíràn mọ́. 40 pa àwọn ìlànà àti àṣẹ rẹ̀ mọ́ mo ń fún un yín lónìí; ó ba à le è yẹ yín, ̀yin le è pẹ́ ilẹ̀ Olúwa Ọlọ́run yín fún un yín gbogbo ìgbà.

Àwọn ìlú ààbò

41 Mose ya àwọn ìlú mẹ́ta kan sọ́tọ̀ apá ìwọ̀-oòrùn Jordani. 42 apànìyàn ó máa síbẹ̀, ó ṣi ẹnìkejì rẹ̀ pa, kórìíra rẹ̀ tẹ́lẹ̀ , àti ó ̀kan nínú ìlú wọ̀nyí ó . 43 Àwọn ìlú mẹ́tẹ̀̀ta náà nìwọ̀nyí: Beseri ijù, ilẹ̀ pẹ̀tẹ́lẹ̀, àwọn ọmọ Reubeni; Ramoti Gileadi, ti àwọn ọmọ Gadi àti Golani Baṣani, ti àwọn ará Manase.

Ìfáàrà òfin

44 Èyí ni òfin Mose gbé kalẹ̀ fún àwọn ará Israẹli. 45 Wọ̀nyí ni àwọn ̀, àti ìlànà àti ìdájọ́ Mose fi lélẹ̀ fún ún àwọn ọmọ Israẹli, lẹ́yìn wọ́n ti jáde kúrò Ejibiti. 46 wọ́n ̀àfonífojì Beti-Peori ìlà-oòrùn Jordani; ilẹ̀ Sihoni, ọba àwọn Amori ó jẹ ọba Heṣboni Mose àti àwọn ọmọ Israẹli ṣẹ́gun, wọ́n ṣe ń ti Ejibiti bọ̀. 47 Wọ́n gba ilẹ̀ rẹ̀, àti ilẹ̀ Ogu ọba Baṣani àwọn ọba Amori méjèèjì ń bẹ ìlà-oòrùn Jordani. 48 Ilẹ̀ wọ̀nyí bẹ̀rẹ̀ láti Aroeri etí odò Arnoni orí òkè Sirioni (èyí ni Hermoni). 49 Àti gbogbo aginjù ìlà-oòrùn Jordani títí Òkun Iyọ̀ ìsàlẹ̀ gẹ̀rẹ́gẹ̀rẹ́ Pisga.

Veja também

Publicidade
Bíblia Online Bíblia Online

Bíblia Online • Versão: 2026-06-28_14-13-17-