Pular para o conteúdo
Publicidade

Êxodo 2

2 2.2: Ap 7.20; Hb 11.23.Obìnrin náà lóyún, ó ọmọkùnrin kan. Nígbà ó í ọmọ náà rẹwà, ó gbé ọmọ náà pamọ́ fún oṣù mẹ́ta. 3 Ṣùgbọ́n nígbà le è gbé e pamọ́ mọ́, ó fi ewé papirusi hun apẹ̀rẹ̀, ó fi ̀àti òjé igi sán apẹ̀rẹ̀ náà. Ó tẹ́ ọmọ náà sínú rẹ̀, ó gbe é inú eèsún ni etí odò Naili.

Veja também