Publicidade

Êxodo 33

1 Olúwa sọ fún Mose , "Fi ìhín yìí sílẹ̀, ìwọ àti àwọn ènìyàn o gòkè láti Ejibiti , gòkè lọ ilẹ̀ Èmi ti pinnu ìbúra fún Abrahamu, Isaaki àti Jakọbu , Èmi yóò fi fún irú-ọmọ rẹ.2 Èmi yóò rán angẹli ṣáájú yín, Èmi yóò àwọn Kenaani, àwọn ará Amori, àwọn ará Hiti, àwọn ará Peresi, àwọn ará Hifi àti àwọn ará Jebusi jáde. 3 gòkè lọ ilẹ̀ ó ń sàn fún wàrà àti oyin. Ṣùgbọ́n èmi lọ pẹ̀yín, nítorí ènìyàn ọlọ́rùn líle ni ̀yin, èmi ba à run yín ̀."

4 Nígbà àwọn ènìyàn náà gbọ́ ̀rọ̀ ìparun wọ̀nyí, wọ́n bẹ̀rẹ̀ kùn, ẹnìkankan le è wọ ohun ̀ṣọ́ rẹ̀. 5 Nítorí Olúwa ti fún Mose , "Sọ fún àwọn ọmọ Israẹli , Ènìyàn Ọlọ́rùn líle ̀yin, Èmi àárín yín ni ìṣẹ́kan, Èmi pa yín run. Nísìnsinyìí, bọ́ ohun ̀ṣọ́ rẹ kúrò, Èmi yóò gbèrò ohun Èmi yóò ṣe pẹ̀rẹ.’ " 6 Bẹ́̀ àwọn ọmọ Israẹli bọ́ ohun ̀ṣọ́ wọn kúrò lára wọn òkè Horebu.

Àgọ́ àjọ

7 Mose máa ń gbé àgọ́ náà, ó pa á ìta ibùdó, ó jìnnà díẹ̀ ibùdó, ó é ni "Àgọ́ àjọ." Ẹnikẹ́ni ó ń béèrè Olúwa yóò lọ ibi àgọ́ àjọ náà ìta ibùdó. 8 Nígbàkígbà Mose jáde lọ ibi àgọ́, gbogbo ènìyàn á dìde, wọ́n á dúró ẹnu-ọ̀àgọ́ wọn, wọn yóò máa wo Mose títí yóò fi wọ inú àgọ́ náà. 9 Mose ṣe wọ inú àgọ́ náà, ̀wọ́n àwọsánmọ̀ yóò sọ̀kalẹ̀, yóò dúró ẹnu ọnà, nígbà Olúwa ń sọ̀rọ̀ pẹ̀Mose. 10 Nígbàkígbà àwọn ènìyàn i ti ̀wọ́n àwọsánmọ̀ dúró ẹnu-ọ̀àgọ́, gbogbo wọn yóò dìde wọn yóò sìn, olúkúlùkù ẹnu-ọ̀àgọ́ rẹ̀. 11 Olúwa máa ń Mose sọ̀rọ̀ lójúkojú, gẹ́gẹ́ i ènìyàn ń ̀rẹ́ rẹ̀ sọ̀rọ̀. Nígbà náà ni Mose yóò tún padà lọ ibùdó, ṣùgbọ́n ̀dọ́mọkùnrin Joṣua ìránṣẹ́ rẹ̀ ọmọ Nuni fi àgọ́ sílẹ̀.

Mose àti ògo Olúwa

12 Mose sọ fún Olúwa , "Ìwọ ti ń sọ fún mi, Darí àwọn ènìyàn wọ̀nyí,ṣùgbọ́n ìwọ jẹ́ ń mọ ẹni ìwọ yóò rán pẹ̀mi. Ìwọ ti , Èmi mọ̀ ́n nípa orúkọ, ìwọ ti ojúrere mi pẹ̀.13 ìwọ inú dídùn pẹ̀mi, kọ́ mi ̀rẹ, èmi ó mọ̀ ́n, n le máa ojúrere rẹ pẹ̀. Rántí orílẹ̀-èdè yìí ènìyàn rẹ ni."

14 Olúwa dáhùn , "Ojú mi yóò máa lọ, Èmi yóò fún ìsinmi."

15 Nígbà náà ni, Mose fún un , "ojú rẹ wa lọ, ṣe rán wa gòkè láti ìhín lọ. 16 Báwo ni ẹnikẹ́ni yóò ṣe mọ̀ inú rẹ dùn pẹ̀mi àti pẹ̀àwọn ènìyàn rẹ àyàfi ti o wa lọ? ni yóò àti àwọn ènìyàn rẹ kúrò lára gbogbo ènìyàn ó ayé?"

17 Olúwa sọ fún Mose , "Èmi yóò ṣe ohun gbogbo ìwọ ti béèrè, nítorí inú mi dún o, Èmi mọ̀ ́n nípa orúkọ rẹ̀."

18 Mose , "Nísinsin yìí fi ògo rẹ hàn ."

19 Olúwa , "Èmi yóò gbogbo ìre kọjá níwájú rẹ, Èmi yóò pòkìkí orúkọ Olúwa níwájú rẹ. Èmi yóò ṣàánú fún ẹni Èmi yóò ṣàánú fún, Èmi yóò ṣoore-ọ̀fẹ́ fún ẹni Èmi yóò ṣoore-ọ̀fẹ́ fún. 20 Ṣùgbọ́n," ó , "Ìwọ le è ojú mi, nítorí ènìyàn kan ń mi, ó ."

21 Olúwa , "Ibìkan lẹ́gbẹ̀́ ̀dọ̀ mi, níbi o ti dúró lórí àpáta. 22 Nígbà ògo mi kọjá, Èmi yóò gbé sínú pàlàpálá àpáta, Èmi yóò ́ pẹ̀ọwọ́ mi títí Èmi yóò fi rékọjá. 23 Nígbà Èmi yóò ọwọ́ mi kúrò, ìwọ yóò ̀yìn mi; ṣùgbọ́n ojú mi ni o ."

Veja também

Publicidade
Bíblia Online Bíblia Online

Bíblia Online • Versão: 2026-06-28_14-13-17-