Pular para o conteúdo
Publicidade

Josué 21

Àwọn ìlú àwọn ọmọ Lefi

1 21.1-42: Nu 35.1-8; 1Ki 6.54-81. Báyìí ni olórí ìdílé àwọn ọmọ Lefi lọ Eleasari àlùfáà, Joṣua ọmọ Nuni àti olórí ̀àwọn ìdílé ̀Israẹli. 2 Ṣilo, Kenaani, wọn sọ fún wọn , "Olúwa pàṣẹ nípasẹ̀ Mose wọn fún wa ìlú láti máa gbé àti ilẹ̀ pápá oko tútù fún ẹran ̀sìn wa."

3 Àwọn ọmọ Israẹli fún àwọn ọmọ Lefi àwọn ìlú wọ̀nyí, àti ilẹ̀ pápá oko tútù lára ilẹ̀ ìní tiwọn gẹ́gẹ́ Olúwa ti pàṣẹ fún Mose.

4 Ìpín kìn-ín-ní fún àwọn ọmọ Kohati, agbo ilé, agbo ilé. Àwọn ọmọ Lefi wọ́n jẹ́ ọmọ Aaroni àlùfáà ni a pín ìlú mẹ́tàlá fún láti ara ̀Juda, Simeoni àti Benjamini.

5 Ìyókù àwọn ọmọ Kohati ni a pín ìlú mẹ́wàá fún láti ara ̀Efraimu, Dani àti ìdajì Manase.

6 Àwọn ̀Gerṣoni ni a pín ìlú mẹ́tàlá fún láti ara ̀Isakari, Aṣeri, Naftali àti ìdajì ̀Manase Baṣani.

7 Àwọn ọmọ Merari agbo ilé, agbo ilé ni wọ́n fún ìlú méjìlá láti ara ̀Reubeni, Gadi àti Sebuluni.

8 Báyìí ni àwọn ọmọ Israẹli pín ìlú wọ̀nyí àti ilẹ̀ pápá oko tútù fún àwọn ọmọ Lefi gẹ́gẹ́ Olúwa ti pàṣẹ láti ẹnu Mose.

9 Láti ara ̀Juda àti ̀Simeoni ni wọ́n ti pín àwọn ìlú a dárúkọ wọ̀nyí, 10 (ìlú wọ̀nyí ni a fún àwọn ọmọ Aaroni ó jẹ́ ̀kan nínú ìdílé Kohati í ṣe ọmọ Lefi, nítorí ìpín àkọ́kọ́ jẹ́ tiwọn).

11 Wọ́n fún wọn Kiriati-Arba (í ṣe, Hebroni), pẹ̀ilẹ̀ pápá oko tútù ó wọn , ilẹ̀ òkè Juda. (Arba ni baba ńlá Anaki.) 12 Ṣùgbọ́n àwọn oko àti àwọn abúlé agbègbè ìlú náà ni wọ́n ti fi fún Kalebu ọmọ Jefunne gẹ́gẹ́ ohun ìní rẹ̀. 13 àfikún wọ́n fún àwọn ọmọ Aaroni í ṣe àlùfáà Hebroni (̀kan nínú ìlú ààbò fún àwọn apànìyàn) pẹ̀ilẹ̀ pápá oko tútù rẹ̀, Libina, 14 Jattiri, Eṣitemoa, 15 Holoni àti Debiri, 16 Aini, Jutta àti Beti-Ṣemeṣi, pẹ̀ilẹ̀ pápá oko wọn. Ìlú mẹ́sàn-án láti ara ̀méjì wọ̀nyí.

17 Láti ara ̀Benjamini ni wọ́n ti fún wọn :

Gibeoni, Geba, 18 Anatoti àti Almoni, pẹ̀ilẹ̀ pápá oko wọn, wọ́n jẹ́ ìlú mẹ́rin.

19 Gbogbo ìlú àwọn àlùfáà, ìran Aaroni jẹ́ mẹ́tàlá pẹ̀ilẹ̀ pápá wọn.

20 Ìyókù ìdílé Kohati ó jẹ́ ọmọ Lefi a pín ìlú fún láti ara ̀Efraimu.

21 ilẹ̀ òkè Efraimu wọ́n fún wọn :

Ṣekemu (ó jẹ́ ìlú ààbò fún apànìyàn) àti Geseri, 22 Kibasaimu àti Beti-Horoni, pẹ̀ilẹ̀ pápá oko wọn jẹ́ ìlú mẹ́rin.

23 Láti ara ̀Dani ni wọ́n ti fún wọn :

Elteke, Gibetoni, 24 Aijaloni àti Gati-Rimoni, pẹ̀ilẹ̀ pápá oko tútù wọn jẹ́ ìlú mẹ́rin.

25 Láti ara ìdajì ̀Manase ni wọ́n ti fún wọn :

Taanaki àti Gati-Rimoni pẹ̀ilẹ̀ pápá oko wọn jẹ́ ìlú méjì.

26 Gbogbo ìlú mẹ́wẹ̀̀yìí àti ilẹ̀ pápá wọn ni a fi fún ìyókù ìdílé Kohati.

27 Àwọn ọmọ Gerṣoni ìdílé àwọn ọmọ Lefi ni wọ́n fún lára:

ìdajì ̀Manase,

Golani Baṣani (ìlú ààbò fún apànìyàn) àti Be-Eṣterah pẹ̀ilẹ̀ pápá oko tútù wọ́n jẹ́ méjì.

28 Láti ara ̀Isakari ni wọ́n ti fún wọn ,

Kiṣioni Daberati, 29 Jarmatu àti Eni-Gannimu, pẹ̀ilẹ̀ pápá oko wọ́n jẹ́ ìlú mẹ́rin.

30 Láti ara ̀Aṣeri ni wọ́n ti fún wọn

Miṣali, àti Abdoni, 31 Helikati àti Rehobu, pẹ̀ilẹ̀ pápá oko wọ́n jẹ́ ìlú mẹ́rin.

32 Láti ara ̀Naftali ni a ti fún wọn :

Kedeṣi Galili (ó jẹ́ ìlú ààbò fún apànìyàn), Hamoti Dori àti Karitani, pẹ̀ilẹ̀ pápá oko wọ́n jẹ́ ìlú mẹ́ta.

33 Gbogbo ìlú ó jẹ́ ti ọmọ Gerṣoni jẹ́ mẹ́tàlá, pẹ̀ilẹ̀ pápá oko wọn.

34 Láti ara ̀Sebuluni ni a ti fún ìdílé Merari (í ṣe ìyókù ọmọ Lefi) :

Jokneamu, Karta, 35 Dimina àti Nahalali, pẹ̀ilẹ̀ pápá oko wọn, wọ́n jẹ́ ìlú mẹ́rin.

36 Láti ara ̀Reubeni ni wọ́n ti fún wọn

Beseri, àti Jahisa, 37 Kedemoti àti Mefaati, pẹ̀ilẹ̀ pápá oko wọ́n jẹ́ ìlú mẹ́rin.

38 Láti ara ̀Gadi ni wọ́n ti fún wọn

Ramoti Gileadi (ó jẹ́ ìlú ààbò fún apànìyàn), Mahanaimu, 39 Heṣboni àti Jaseri, e pẹ̀ilẹ̀ pápá oko wọ́n jẹ́ ìlú mẹ́rin.

40 Gbogbo ìlú wọ́n pín fún àwọn ọmọ Merari wọ́n jẹ́ ìyókù àwọn ọmọ Lefi jẹ́ méjìlá.

41 Gbogbo ìlú àwọn ọmọ Lefi láàrín ara ilẹ̀ àwọn ọmọ Israẹli jẹ́ méjìdínláàádọ́ta lápapọ̀ pẹ̀pápá oko wọn. 42 ̀kọ̀̀kan ìlú wọ̀nyí ni ó ni ilẹ̀ pápá oko ó ì , bẹ́̀ náà fún gbogbo ìlú wọ̀nyí.

43 Báyìí ni Olúwa fún Israẹli gbogbo ilẹ̀ ó ṣèlérí láti fi fún àwọn baba ńlá wọn. Nígbà wọ́n gbà á tan wọ́n tẹ̀síbẹ̀. 44 Olúwa fún wọn ìsinmi gbogbo ̀, gẹ́gẹ́ ó ti ṣèlérí fún baba ńlá wọn. ̀kankan nínú àwọn ̀wọn ó dojúkọ wọ́n. Olúwa fi gbogbo àwọn ̀wọn wọn ọwọ́. 45 ̀kan nínú ìlérí rere Olúwa ṣe fún ilé Israẹli ó kùnà, gbogbo rẹ̀ ni ó ṣe.

Veja também