Publicidade

Josué 23

̀rọ̀ ìdágbére Joṣua àwọn olórí

1 Lẹ́yìn ọjọ́ pípẹ́, nígbà Olúwa ti fún Israẹli ìsinmi kúrò ọwọ́ àwọn ̀wọn ó wọn , nígbà náà Joṣua ti di arúgbó. 2 Ó pe gbogbo Israẹli jọ: àgbàgbà wọn, olórí wọn, adájọ́ àti àwọn ìjòyè, ó sọ fún wọn , "Èmi ti pọ̀ ọdún èmi ti di arúgbó. 3 ̀yin tìkára yín ti ohun gbogbo Olúwa Ọlọ́run yín ti ṣe gbogbo orílẹ̀-èdè wọ̀nyí nítorí yín, Olúwa Ọlọ́run yín ni ó fún yín. 4 rántí mo ṣe pín ogún ìní fún àwọn ̀yín ilẹ̀ orílẹ̀-èdè gbogbo ó ; àwọn orílẹ̀-èdè mo ti ṣẹ́gun àárín Jordani àti Òkun Ńlá ìwọ̀-oòrùn. 5 Olúwa Ọlọ́run yín fúnra rẹ̀ yóò wọn jáde kúrò ̀yín, yóò wọ́n jáde iwájú yín, ̀yin yóò gba ilẹ̀ ìní wọn, gẹ́gẹ́ Olúwa Ọlọ́run ti ṣe ìlérí fún yín.

6 "jẹ́ alágbára gidigidi, ṣọ́ra láti ṣe ìgbọ́ràn ohun a kọ inú ìwé òfin Mose, láìyí padà ̀tún tàbí òsì. 7 ṣe àjọṣepọ̀ pẹ̀àwọn orílẹ̀-èdè ó ṣẹ́láàrín yín; ṣe pe orúkọ òrìṣà wọn tàbí fi wọ́n búra. gbọdọ̀ sìn wọ́n tàbí ki tẹríba fún wọn. 8 Ṣùgbọ́n di Olúwa Ọlọ́run yín ṣinṣin gẹ́gẹ́ ti ń ṣe tẹ́lẹ̀ títí di àkókò yìí.

9 "Olúwa ti àwọn orílẹ̀-èdè ńlá àti alágbára kúrò níwájú yín; títí di òní yìí ẹnìkan ó le dojúkọ yín. 10 ̀kan nínú yín ẹgbẹ̀rún (1,000) ̀, nítorí Olúwa Ọlọ́run yín fún yín gẹ́gẹ́ ó ti ṣe ìlérí. 11 Bẹ́̀ ni ṣọ́ra gidigidi láti fẹ́ràn Olúwa Ọlọ́run yín.

12 "Ṣùgbọ́n padà, gba ìmọ̀ pọ̀ pẹ̀àwọn ṣẹ́lára àwọn orílẹ̀-èdè ó láàrín yín, ń fọmọ fún ara yín ìyàwó, wọn àjọṣepọ̀. 13 Nígbà náà ni ó mọ̀ dájú Olúwa Ọlọ́run yín yóò àwọn orílẹ̀-èdè wọ̀nyí jáde mọ́ kúrò níwájú yín. Dípò èyí, wọn yóò jẹ́ ìkẹ́kùn àti tàkúté fún un yín, pàṣán ̀yin yín àti ̀gún ojú yín, títí ó fi ṣègbé kúrò ilẹ̀ dáradára , èyí Olúwa Ọlọ́run yín ti fi fún yín.

14 "Nísinsin yìí èmi ti fẹ́ máa lọ ibi àwọn àgbà ń . mọ̀ pẹ̀gbogbo ọkàn yín àti àyà yín , ohun kan ó kùnà nínú àwọn ìlérí rere gbogbo Olúwa Ọlọ́run yín fi fún un yín. Gbogbo ìlérí ti ṣe ̀kan ó kùnà. 15 Ṣùgbọ́n gẹ́gẹ́ ìlérí dáradára gbogbo ti Olúwa Ọlọ́run yín ti ìmúṣẹ, bẹ́̀ ni Olúwa yóò ibi gbogbo ó ti kìlọ̀ orí yín, títí yóò fi pa yín run kúrò ilẹ̀ dáradára ó ti fi fún un yín. 16 sẹ̀ májẹ̀Olúwa Ọlọ́run yín, èyí ó pàṣẹ fún un yín, lọ sin àwọn òrìṣà tẹ orí ba fún wọn, ìbínú gbígbóná Olúwa yóò sórí i yín, ̀yin yóò ṣègbé kíákíá kúrò ilẹ̀ dáradára ó ti fi fún un yín."

Veja também

Publicidade
Bíblia Online Bíblia Online

Bíblia Online • Versão: 2026-06-29_22-07-56-