Publicidade

Josué 6

1 Wàyí o, a ti Jeriko mọ́gágá nítorí àwọn ọmọ Israẹli, ẹnikẹ́ni jáde, ẹnikẹ́ni wọlé.

2 Nígbà náà ni Olúwa fún Joṣua , "ó, mo ti fi Jeriko lọ́wọ́ pẹ̀ọba rẹ̀ àti àwọn jagunjagun rẹ̀. 3 wọ́de ogun ìlú náà lẹ́̀kan pẹ̀gbogbo àwọn jagunjagun. ṣe èyí fún ọjọ́ mẹ́. 4 Jẹ́ àwọn àlùfáà méje gbé fèrè ìwo àgbò iwájú àpótí ̀. ọjọ́ keje, wọ́de ogun ìlú náà ìgbà méje, pẹ̀àwọn àlùfáà ń fọn fèrè. 5 Nígbà gbọ́ ohùn fèrè náà, àwọn ènìyàn yèè igbe ńlá, nígbà náà ni odi ìlú náà yóò lulẹ̀, àwọn ènìyàn yóò lọ òkè, olúkúlùkù yóò wọ inú rẹ̀ lọ tààrà."

6 Bẹ́̀ ni Joṣua ọmọ Nuni pe àwọn àlùfáà ó fún wọn , "gbé àpótí ̀Olúwa náà àwọn àlùfáà méje ó ru fèrè ìwo iwájú u rẹ̀." 7 Ó pàṣẹ fún àwọn ènìyàn náà , "lọ, ìlú náà pẹ̀àwọn olùṣọ́ ó hámọ́ra kọjá iwájú àpótí ̀Olúwa."

8 Nígbà Joṣua ti àwọn ènìyàn sọ̀rọ̀ tán, àwọn àlùfáà méje wọ́n gbé fèrè méje iwájú Olúwa kọjá iwájú, wọ́n fọn fèrè wọn, àpótí ̀Olúwa tẹ̀wọn. 9 Àwọn olùṣọ ó hámọ́ra lọ níwájú àwọn àlùfáà ń fọn fèrè, olùṣọ́ ̀yìn tẹ̀àpótí ̀náà. gbogbo àsìkò yìí fèrè ń dún. 10 Ṣùgbọ́n Joṣua pàṣẹ fún àwọn ènìyàn , "gbọdọ̀ kígbe ogun, gbọdọ̀ gbé ohùn yín sókè, ṣe sọ ̀rọ̀ kan títí ọjọ́ èmi yóò sọ fún un yín . Nígbà náà ni ̀yin yóò !" 11 Bẹ́̀ ni ó àpótí ̀Olúwa ìlú náà , ó i lẹ́̀kan. Nígbà náà ni àwọn ènìyàn náà padà ibùdó, wọ́n gbé ibẹ̀ fún alẹ́ náà.

12 Joṣua dìde kùtùkùtù òwúrọ̀ ọjọ́ kejì, àwọn àlùfáà gbé àpótí ̀Olúwa. 13 Àwọn àlùfáà méje ó gbé ìpè ìwo àgbò méje ń lọ níwájú àpótí ̀Olúwa, wọ́n ń fọ́n àwọn ìpè: àwọn ó hámọ́ra ogun ń lọ níwájú u wọn; àwọn ọmọ lẹ́yìn ń tọ àpótí ̀Olúwa lẹ́yìn, àwọn àlùfáà ń fọn ìpè wọ́n ti ń lọ. 14 ọjọ́ kejì, wọ́n ìlú náà lẹ́̀kan wọ́n padà ibùdó. Wọ́n ṣe èyí fún ọjọ́ mẹ́.

15 ọjọ́ keje, wọ́n dìde kùtùkùtù òwúrọ̀ àfẹ̀mọ́júmọ́, wọ́n wọ́de ogun ìlú náà ìgbà méje, gẹ́gẹ́ i ti ìṣáájú, ọjọ́ keje nìkan ṣoṣo ni wọ́n wọ́de ogun ìlú náà nígbà méje. 16 ìgbà keje, nígbà àwọn àlùfáà fọn fèrè, Joṣua pàṣẹ fún àwọn ènìyàn , "! Nítorí Olúwa ti fún un yín ìlú náà. 17 Ìlú náà àti gbogbo ohun ó níbẹ̀ ni yóò jẹ́ ìyàsọ́tọ̀ fún Olúwa. Rahabu ó jẹ́ panṣágà nìkan àti gbogbo àwọn ó pẹ̀u rẹ̀ ni a ó ; nítorí ó pa àwọn ayọ́lẹ̀á rán mọ́. 18 pa ara yín mọ́ kúrò nínú ohun ìyàsọ́tọ̀ fún ìparun, ̀yin ó ba à ṣojú kòkòrò nípa mímú nínú àwọn ohun ìyàsọ́tọ̀. ṣe bẹ́̀ ó sọ ibùdó Israẹli di ìparun. wàhálà sórí i rẹ̀. 19 Gbogbo fàdákà àti wúrà àti ohun èlò idẹ àti irin jẹ́ mímọ́ fún Olúwa, wọ́n yóò sínú ìṣúra Olúwa."

20 Nígbà àwọn àlùfáà fọn ìpè, àwọn ènìyàn náà . Ó ṣe, àwọn ènìyàn ti gbọ́ ìró ìpè, àwọn ènìyàn ìhó ńlá, odi ìlú náà lulẹ̀ bẹẹrẹ; bẹ́̀ ni olúkúlùkù ya wọ inú ìlú náà lọ tààrà, wọ́n ìlú náà. 21 Wọ́n ya ìlú náà sọ́tọ̀ fún Olúwa àti fún ìparun, wọ́n fi idà run gbogbo ohun alààyè ìlú náàọkùnrin àti obìnrin, ́mọdé, àti àgbà, màlúù, àgùntàn àti kẹ́tẹ́kẹ́tẹ́.

22 Joṣua sọ fún àwọn ọkùnrin méjì wọ́n ti ṣe ayọ́lẹ̀ilẹ̀ náà , "lọ ilé panṣágà , mu jáde àti gbogbo ohun í ṣe tirẹ̀ gẹ́gẹ́ búra fún un." 23 Bẹ́̀ àwọn ̀dọ́mọkùnrin ó lọ ṣe ayọ́lẹ̀wọlé lọ, wọ́n Rahabu jáde, baba rẹ̀, ìyá rẹ̀, àwọn arákùnrin rẹ̀ àti ohun gbogbo ó . Wọ́n gbogbo ìdílé rẹ̀ jáde, wọ́n fi wọ́n ibìkan ìta ibùdó àwọn ará Israẹli.

24 Nígbà náà ni wọ́n sun gbogbo ìlú náà àti gbogbo ohun ó nínú u rẹ̀, ṣùgbọ́n wọ́n fi fàdákà, wúrà ohun èlò idẹ àti irin sínú ìṣúra ilé Olúwa. 25 Ṣùgbọ́n Joṣua Rahabu panṣágà pẹ̀gbogbo ìdílé e rẹ̀ àti gbogbo ẹni í ṣe tirẹ̀ nítorí , ó pa àwọn ọkùnrin Joṣua rán gẹ́gẹ́ ayọ́lẹ̀Jeriko mọ́. Ó ń gbé láàrín ará Israẹli títí di òní yìí.

26 6.26: 1Ọb 16.34. àkókò náà Joṣua búra , "Ègún ni fún ẹni náà níwájú Olúwa yóò dìde, yóò tún ìlú Jeriko kọ́:

"Pẹ̀ikú àkọ́ọmọ rẹ̀ ni

yóò fi pilẹ̀ rẹ̀;

ikú àbíkẹ́yìn rẹ̀ yóò fi

gbé ìlẹ̀kùn bodè rẹ̀ ."

27 Bẹ́̀ ni Olúwa pẹ̀Joṣua; òkìkí rẹ̀ kàn gbogbo ilẹ̀ náà.

Veja também

Bíblia Online Bíblia Online

Bíblia Online • Versão: 2026-07-05_12-11-46-