Publicidade

Juízes 6

Gideoni

1 Àwọn ọmọ Israẹli túnṣe ohun ó burú ojú Olúwa, Ó fi wọ́n àwọn ará Midiani lọ́wọ́ fún ọdún méje. 2 Agbára àwọn ará Midiani pọ̀ púpọ̀ lórí àwọn Israẹli, wọ́n hùwà ipá wọn, nítorí ìdí èyí, àwọn Israẹli sálọ àwọn orí òkè, wọ́n kọ́ àgọ́ fún ara wọn nínú ihò àpáta, àti nínú ̀gbun àti ibi agbára nínú àpáta. 3 ìgbàkúgbà àwọn ọmọ Israẹli ti gbin ̀gbìn wọn, àwọn ará Midiani, àwọn ará Amaleki àti àwọn ará ìlà-oòrùn mìíràn yóò láti wọn . 4 Wọn yóò tẹ̀orí ilẹ̀ náà, wọn a irúgbìn wọ̀nyí jẹ́ títí Gasa, wọn í í fi ohun alààyè kankan sílẹ̀ fún àwọn ọmọ Israẹli, à ṣe àgùntàn, màlúù tàbí kẹ́tẹ́kẹ́tẹ́. 5 Wọn a máa pẹ̀ohun ̀sìn wọn àti àwọn àgọ́ wọn, wọn a dàbí eṣú nítorí i púpọ̀ wọn. Ènìyàn ka iye àwọn ènìyàn náà bẹ́̀ ni àwọn ìbákasẹ, wọ́n pọ̀ bi wọn ṣe é iye, wọn a bo ilẹ̀ náà wọn a jẹ ́ run. 6 Àwọn ará Midiani pọ́n àwọn ọmọ Israẹli lójú, wọ́n sọ wọ́n di òtòṣì àti aláìní, fún ìdí èyí wọ́n pe Olúwa nínú àdúrà fún ìrànlọ́wọ́.

7 Nígbà àwọn ọmọ Israẹli pe Olúwa nítorí àwọn ará Midiani. 8 Olúwa fi etí igbe wọn, ó rán wòlíì kan wọn, ẹni ó , "Èyí ni ohun Olúwa Ọlọ́run Israẹli : mo yín gòkè ti Ejibiti , láti oko ẹrú. 9 Mo gbà yín kúrò nínú agbára Ejibiti àti kúrò ọwọ́ gbogbo àwọn aninilára yín. Mo wọn kúrò iwájú yín, mo fi ilẹ̀ wọn fún yín. 10 Mo fún un yín , Èmi ni Olúwa Ọlọ́run yín; ṣe sin àwọn òrìṣà àwọn ará Amori, ilẹ̀ ẹni ̀yin ń gbé.Ṣùgbọ́n ̀yin gbọ́rọ̀ ohun mo sọ."

11 ọjọ́ kan angẹli Olúwa , ó jókòó abẹ́ igi óákù Ofira èyí ti ṣe ti Joaṣi ará Abieseri, níbi Gideoni ọmọ rẹ̀ ti ń lu ọkà jéró, níbi ìpọntí wáìnì láti fi pamọ́ kúrò níwájú àwọn ará Midiani. 12 Nígbà angẹli Olúwa fi ara han Gideoni, ó fún un , "Olúwa pẹ̀rẹ, akọni ológun."

13 Gideoni dáhùn , "Alàgbà, Olúwa pẹ̀wa, gbogbo ìwọ̀nyí fi ń ṣẹlẹ̀ wa? Níbi gbogbo àwọn iṣẹ́ ìyanu rẹ àwọn baba wa ròyìn rẹ̀ fún wa nígbà wọ́n , Olúwa ha wa gòkè láti ilẹ̀ Ejibiti ?Ṣùgbọ́n nísinsin yìí Olúwa ti kọ̀ sílẹ̀, ó ti fi àwọn ará Midiani lọ́wọ́."

14 Olúwa yípadà i, ó fún un , "Lọ nínú agbára o yìí, o gba àwọn ará Israẹli sílẹ̀ kúrò lọ́wọ́ àwọn ará Midiani. Èmi ni ó ń rán lọ."

15 Gideoni dáhùn , "Yéè olúwa mi, ̀wo ni èmi yóò fi gba Israẹli ? Ìdílé mi ni ó jẹ́ aláìlera Manase, àti èmi ni ó kéré ìdílé baba mi."

16 Olúwa dáhùn , "Èmi yóò pẹ̀rẹ, ìwọ yóò pa gbogbo àwọn ará Midiani láì ku ẹnìkankan."

17 Gideoni dáhùn , nísinsin yìí mo ojúrere rẹ pàdé, fún mi àmì ìwọ ni ń mi sọ̀rọ̀. 18 Jọ̀wọ́ ṣe kúrò níbí títí èmi yóò fi ọrẹ fún n gbé e iwájú rẹ.

Olúwa , "Èmi yóò dúró títí ìwọ yóò fi ."

19 Gideoni yára wọ ilé lọ, ó pa ̀dọ́ ewúrẹ́ kan, wọ́n é, ó ìyẹ̀fun efa kan, ó fi ṣe àkàrà aláìwú. Ó gbé ẹran náà sínú agbọ̀n, ṣùgbọ́n ó fi ọbẹ̀ rẹ̀ sínú ìkòkò, ó gbé wọn jáde tọ angẹli náà ọrẹ lábẹ́ igi óákù.

20 Angẹli Ọlọ́run náà fún un , "Gbé ẹran náà àti àkàrà àìwú náà, orí àpáta yìí, o da omi ọbẹ̀ rẹ̀ orí rẹ̀." Gideoni ṣe bẹ́̀. 21 Angẹli Olúwa fi orí ̀ó ọwọ́ rẹ̀ kan ẹran àti àkàrà àìwú náà. Iná jáde láti inú àpáta, ó ẹran àti àkàrà náà, angẹli náà mọ́. 22 Nígbà Gideoni ti mọ̀ dájúdájú angẹli Olúwa ni, ó , "Háà! Olúwa Olódùmarè! Mo ti angẹli Olúwa ojúkorojú!"

23 Ṣùgbọ́n Olúwa fún un , "Àlàáfíà! ṣe bẹ̀, ìwọ yóò kùú."

24 Báyìí ni Gideoni mọ pẹpẹ kan fún Olúwa níbẹ̀, ó pe orúkọ rẹ̀ "Àlàáfíà ni Olúwa." Ó Ofira ti Abieseri títí di òní.

25 òru ọjọ́ náà Olúwa fún un , akọ màlúù baba rẹ, àní akọ màlúù kejì ọlọ́dún méje. pẹpẹ Baali baba rẹ lulẹ̀, o bẹ́ igi ère òrìṣà Aṣerah ó ̀gbẹ́ rẹ̀ lulẹ̀. 26 Lẹ́yìn èyí o mọ pẹpẹ èyí ó yẹ fún Olúwa Ọlọ́run rẹ lórí òkè yìí. o akọ màlúù kejì, o igi ère òrìṣà Aṣerah ìwọ bẹ́ lulẹ̀ ẹbọ sísun Olúwa.

27 Gideoni mẹ́wàá nínú àwọn ìránṣẹ́ rẹ̀, ó ṣe Olúwa ti pàṣẹ fún un ṣùgbọ́n, nítorí ó bẹ̀àwọn ará ilé baba rẹ̀ àti àwọn ènìyàn ìlú náà ṣe é ̀sán, òru ni ó ṣe.

28 Nígbà ilẹ̀ ọjọ́ kejì mọ́, àwọn ènìyàn ìlú náà , wọ́n i àti fọ́ pẹpẹ Baali àti a ti bẹ́ igi ère òrìṣà Aṣerah ó ̀gbẹ́ rẹ̀, a ti fi akọ màlúù kejì ẹbọ lórí pẹpẹ a ṣẹ̀ṣẹ̀ mọ.

29 Àwọn ènìyàn ìlú náà bi ara wọn , "Ta ni ó ṣe èyí?"

Lẹ́yìn wọn fi ara balẹ̀ ṣe ìwádìí, wọ́n gbọ́ , "Gideoni ọmọ Joaṣi ni ó ṣe é."

30 Àwọn ọkùnrin ìlú náà fún Joaṣi , "ọmọ rẹ jáde . Ó láti nítorí ó ti pẹpẹ Baali lulẹ̀ ó ti ère òrìṣà Aṣerah ó ̀rẹ̀ lulẹ̀."

31 Ṣùgbọ́n Joaṣi bi àwọn èrò wọ́n fi ìbínú dúró í , "̀yin yóò ha gbìjà Baali ? ̀yin yóò ha gbà á sílẹ̀ ? Ẹnikẹ́ni ó gbìjà rẹ̀ kíkú ni olúwa rẹ̀ yóò òwúrọ̀. Baali ṣe Ọlọ́run nítòótọ́ yóò fún ara rẹ̀ ẹnikẹ́ni pẹpẹ rẹ̀ lulẹ̀." 32 Fún ìdí èyí ọjọ́ náà wọ́n pe Gideoni "Jerubbaali" , "Jẹ́ Baali a ," nítorí ó ti pẹpẹ Baali.

33 Láìpẹ́ jọjọ, àwọn ogun àwọn Midiani, ti àwọn Amaleki àti ti àwọn ènìyàn ìhà ìlà-oòrùn yòókù ara wọn jọ pọ̀ ìṣọ̀kan, wọ́n kọjá Jordani wọ́n tẹ̀àfonífojì Jesreeli. 34 ̀Olúwa Gideoni, ó fun fèrè ìpè, láti pe àwọn ará Abieseri láti tẹ̀òun. 35 Ó rán àwọn oníṣẹ́ la ilẹ̀ Manase wọ́n dira ogun, àti Aṣeri, Sebuluni àti Naftali gbogbo pẹ̀lọ láti pàdé wọn.

36 Gideoni fún Ọlọ́run , "ìwọ yóò gba Israẹli nípasẹ̀ mi ìwọ ti ṣe ìlérí37 kíyèsi, èmi yóò fi awọ irun àgùntàn ilẹ̀ ìpakà alẹ́ òní. ìrì sẹ̀ orí awọ yìí nìkan gbogbo ilẹ̀ yòókù gbẹ, nígbà náà ni èmi yóò mọ̀ lóòótọ́ ìwọ yóò gba Israẹli nípasẹ̀ mi ìwọ ti sọ." 38 Èyí ni ó ṣẹlẹ̀. Nígbà Gideoni òwúrọ̀ ọjọ́ kejì, ó fún irun àgùntàn náà, ọpọ́n omi kan kún.

39 Gideoni tún fún Ọlọ́run , "Jọ̀wọ́ ṣe bínú mi, ṣùgbọ́n jẹ́ n tún ìdánilójú kan i, èmi bẹ̀ ́ jẹ́ n fi awọ irun yìí ṣe ìdánwò kan i. àsìkò yìí, jẹ́ awọ irun yìí gbẹ gbogbo ilẹ̀ tutù pẹ̀ìrì." 40 òru náà Ọlọ́run ṣe bẹ́̀, awọ irun àgùntàn nìkan ni ó gbẹ; gbogbo ilẹ̀ yòókù tutù nítorí ìrì.

Veja também

Bíblia Online Bíblia Online

Bíblia Online • Versão: 2026-07-05_19-25-13-