Publicidade

Levítico 25

Ọdún ìsinmi

1 Olúwa sọ fún Mose orí òkè Sinai , 2 "Sọ fún àwọn ọmọ Israẹli, o fún wọn , Nígbà ilẹ̀ náà èmi ó fi fún yín, ilẹ̀ náà gbọdọ̀ sinmi fún Olúwa. 3 Ọdún mẹ́ni ìwọ ó fi gbin oko rẹ, ọdún mẹ́ni ìwọ ó fi tọ́ọgbà àjàrà rẹ, ìwọ ó fi èso wọn jọ. 4 Ṣùgbọ́n ọdún keje ilẹ̀ náà ìsinmi: ìsinmi fún Olúwa. Bẹ́̀ ni ìwọ gbọdọ̀ tọ́ọgbà àjàrà rẹ. 5 ṣe kórè ohun ó tìkára rẹ̀ , ṣe kórè èso àjàrà ọgbà ò tọ́. Ilẹ̀ náà gbọdọ̀ ìsinmi fún ọdún kan. 6 Ohunkóhun ilẹ̀ náà jáde ọdún ìsinmi ni yóò jẹ́ oúnjẹ fún yín àní fún ̀yin tìkára yín, àwọn ìránṣẹ́kùnrin àti ìránṣẹ́bìnrin yín, àwọn alágbàṣe àti àwọn ń gbé pẹ̀yín fún ìgbà díẹ̀. 7 Fún àwọn ohun ̀sìn yín, àti àwọn ẹranko búburú ilẹ̀ yín. Ohunkóhun ilẹ̀ náà jáde jẹ.

Ọdún ìdásílẹ̀

8 " Ọdún ìsinmi méje èyí í ṣe ọdún mọ́kàndínláàádọ́ta (49) ni . 9 Lẹ́yìn náà, fọn fèrè gbogbo ibikíbi ọjọ́ kẹwàá oṣù keje ọjọ́ ìwẹ̀nùmọ́. ọjọ́ ètùtù yìí, fọn fèrè yíká gbogbo ilẹ̀ yín. 10 ya àádọ́ta ọdún náà sọ́tọ̀ kéde òmìnira fún gbogbo ẹni ń gbé ilẹ̀ náà. Yóò jẹ́ ọdún ìdásílẹ̀ fún yín. olúkúlùkù padà ilẹ̀ ìní rẹ̀ àti ̀dọ̀ àwọn ẹbí rẹ̀. 11 Àádọ́ta ọdún ni yóò jẹ́ ọdún ìdásílẹ̀ fún yín. ṣe gbin ohunkóhun, gbọdọ̀ kórè ohun ó fúnra rẹ̀ tàbí kórè ọgbà àjàrà . 12 Torí ọdún ìdásílẹ̀ ni ó gbọdọ̀ jẹ́ mímọ́ fún yín. jẹ ohun jáde nínú oko náà.

13 " ọdún ìdásílẹ̀ yìí, olúkúlùkù gbà ohun ìní rẹ̀ padà.

14 " ta ilẹ̀ fún ̀kan nínú àwọn ènìyàn yín tàbí ra èyíkéyìí láti ̀dọ̀ rẹ̀, ṣe rẹ́ ara yín jẹ. 15 ra ilẹ̀ lọ́wọ́ àwọn ènìyàn yín gẹ́gẹ́ iye owó ó ọdún ìdásílẹ̀ , òun náà ta ilẹ̀ fún yín gẹ́gẹ́ iye ọdún rẹ̀ tókù láti kórè. 16 iye ọdún rẹ̀ gùn, iye owó rẹ̀ pọ̀, iye ọdún rẹ̀ kúrú, iye owó rẹ̀ kéré, torí ohun ó gan an iye èso rẹ̀. 17 ṣe rẹ́ ara yín jẹ, ṣùgbọ́n bẹ̀Ọlọ́run. Èmi ni Olúwa Ọlọ́run yín.

18 " tẹ̀àwọn ìlànà mi, kíyèsi láti pa òfin mi mọ́, ba à le máa gbé láìléwu ilẹ̀ náà. 19 Nígbà yìí ni ilẹ̀ náà yóò so èso rẹ̀, ó jẹ àjẹyó, ó máa gbé láìléwu. 20 le béèrè , "ni àwa ó jẹ ọdún keje, a gbin èso a kórè?" 21 Èmi ó pèsè ìbùkún sórí yín bẹ́̀ ilẹ̀ yín yóò so èso fún ọdún mẹ́ta lẹ́yìn rẹ̀. 22 gbin èso yín ọdún kẹjọ, àwọn èso ti tẹ́lẹ̀ ó máa jẹ, títí ìkórè ti ọdún kẹsànán yóò fi .

23 " ṣe ta ilẹ̀ yín àtàpa torí ̀yin kọ́ lẹ ni ín, ti Ọlọ́run ni, ̀yin jẹ́ àjèjì àti ayálégbé. 24 gbogbo orílẹ̀-èdè ìní yín, fi ààyè sílẹ̀ fún ìràpadà ilẹ̀ náà.

25 " ̀kan nínú àwọn ènìyàn yín tálákà, bi ó ta ara àwọn ẹrù rẹ̀, ará ilé rẹ̀ ó súnmọ́ ra ohun ó padà. 26 Ẹni ẹni á padà fún un, òun fúnra rẹ̀ ti lọ́rọ̀, ó ànító láti á. 27 ó mọ iye owó ó jẹ fún iye ọdún ó á, ó iye ó padà fún ẹni ó á fún, lẹ́yìn náà, ó padà ilẹ̀ ìní rẹ̀. 28 Ṣùgbọ́n ̀àti san án padà fún un. Ohun ó ìkáwọ́ ẹni ó á títí di ọdún ìdásílẹ̀. ó a padà fún ẹni ó ni i ọdún ìdásílẹ̀, ẹni ó ni í tẹ́lẹ̀ tún padà gbà ohun ìní rẹ̀.

29 " arákùnrin kan ta ilé gbígbé kan ìlú olódi, ó á padà ìwọ̀n ọdún kan àkókò ó á, ìwọ̀n ọdún kan ni ó á padà. 30 Ṣùgbọ́n á padà láàrín ọdún náà ilé náà ó láàrín ìlú ni ó yọ̀ǹda pátápátá fún ẹni ó á, àti àwọn ìdílé rẹ̀. wọ́n da padà ọdún ìdásílẹ̀. 31 Ṣùgbọ́n àwọn ilé ó abúlé láìní odi ni a gẹ́gẹ́ ilẹ̀ oko, a wọ́n padà, wọ́n da padà ọdún ìdásílẹ̀.

32 " Àwọn ọmọ Lefi ̀tọ́, nígbàkígbà láti ra ilẹ̀ wọn, ó jẹ́ ohun ìní wọn àwọn ìlú ó jẹ́ ti ọmọ Lefi. 33 Torí náà ohun ìní àwọn ọmọ Lefi ni wọ́n padà, fún àpẹẹrẹ, èyí ni ilẹ̀ a ìlúkílùú ó jẹ́ tiwọn, ó gbọdọ̀ di dídápadà ọdún ìdásílẹ̀, torí àwọn ilẹ̀ ó ìlú àwọn Lefi ni ìní wọn láàrín àwọn ará Israẹli. 34 Ṣùgbọ́n ilẹ̀ wọ́n ti ń da ẹran ó jẹ́ ti ìlú wọn, wọn gbọdọ̀ wọ́n, ilẹ̀ ìní wọn láéláé ni.

35 " arákùnrin yín kan tálákà le è pèsè fún àìní ara rẹ̀, pèsè fún un ti ń ṣe fún àwọn àlejò tàbí àwọn gbà sílé: ó ba à le è máa gbé láàrín yín. 36 gbọdọ̀ gba èlé kankan lọ́wọ́ rẹ̀, bẹ̀Olúwa arákùnrin yín le è máa gbé láàrín yín. 37 ṣe gba èlé lórí owó a bẹ́̀ ni gbọdọ̀ jẹ èrè lórí oúnjẹ fún un. 38 Èmi ni Olúwa Ọlọ́run yín ó yín jáde láti ilẹ̀ Ejibiti láti fún yín ilẹ̀ Kenaani àti láti jẹ́ Ọlọ́run yín.

39 " arákùnrin yín kan tálákà bi ó ta ara rẹ̀ fún ẹrú. ṣe ó ẹrú. 40 Jẹ́ ó lọ́dọ̀ rẹ alágbàṣe tàbí àlejò láàrín yín, ó máa ṣiṣẹ́ sìn ́ títí di ọdún ìdásílẹ̀. 41 Nígbà náà ni ó yọ̀ǹda òun àti àwọn ọmọ rẹ̀, wọ́n padà ìdílé wọn àti ilẹ̀ ìní baba wọn. 42 Torí ìránṣẹ́ mi ni àwọn ará Israẹli jẹ́. Ẹni mo jáde láti ilẹ̀ Ejibiti , torí èyí gbọdọ̀ wọ́n lẹ́. 43 ṣe rorò mọ́ wọn: ṣùgbọ́n bẹ̀Ọlọ́run yín.

44 " Àwọn ẹrúkùnrin àti ẹrúbìnrin yín jẹ́ láti orílẹ̀-èdè ó yín , ra àwọn ẹrú wọ̀nyí lọ́wọ́ wọn. 45 Bákan náà, le è ra àwọn àlejò ń gbé láàrín yín, àti àwọn ìdílé wọn a sáàrín yín. Wọn yóò di ohun ìní yín. 46 fi wọ́n sílẹ̀ ogún fún àwọn ọmọ yín, wọ́n sọ wọ́n di ẹrú títí láé. Ṣùgbọ́n gbọdọ̀ rorò mọ́ ọmọ Israẹli kankan.

47 " àlejò kan láàrín yín tàbí ẹni ń gbé àárín yín fún ìgbà díẹ̀ lọ́rọ̀ ọmọ Israẹli tálákà bi ó ta ara rẹ̀ lẹ́fún àlejò tàbí ìdílé àlejò náà. 48 Ó lẹ́tọ̀́ si ki a á padà lẹ́yìn ìgbà ó ti ta ara rẹ̀. ̀kan nínú ìbátan rẹ̀ le è á padà. 49 Àbúrò baba rẹ̀ ọkùnrin tàbí àbúrò rẹ̀ obìnrin tàbí ẹnikẹ́ni ó tan nínú ìdílé rẹ̀ le è wọ̀n padà. ó ti lọ́rọ̀, ó ra ara rẹ̀ padà. 50 òun àti olówó rẹ̀ ka iye ọdún ó ta ara rẹ̀ títí ọdún ìdásílẹ̀ iye owó ìdásílẹ̀ rẹ̀ jẹ́ iye wọ́n ń san lórí alágbàṣe fún iye ọdún náà. 51 iye ọdún rẹ̀ ó ṣẹ́pọ̀, iye owó fún ìràpadà rẹ̀ pọ̀. 52 ó ṣe kìkì ọdún díẹ̀ ni ó títí di ọdún jubili, ó ṣe ìṣirò rẹ̀, ó san owó náà iye ìṣirò rẹ̀ padà. 53 ti ń ṣe i lọ́dọọdún, i dájú olówó rẹ̀ korò mọ́ .

54 " a á padà nínú gbogbo ̀wọ̀nyí, òun àti àwọn ọmọ rẹ̀ sílẹ̀ ọdún ìdásílẹ̀. 55 Nítorí ìránṣẹ́ ni àwọn ọmọ Israẹli jẹ́ fún mi. Ìránṣẹ́ mi ni wọ́n, mo jáde láti Ejibiti . Èmi ni Olúwa Ọlọ́run yín.

Veja também

Publicidade
Bíblia Online Bíblia Online

Bíblia Online • Versão: 2026-06-28_14-13-17-