Publicidade

Levítico 5

1 " ẹnìkan dẹ́ṣẹ̀ nítorí sọ̀rọ̀ nígbà a bi í gbangba jẹ́rìí nípa nǹkan tàbí nǹkan mọ̀ nípa ìṣẹ̀lẹ̀ kan, a ó di ̀bi rẹ̀ ú.

2 " Tàbí ẹnìkan fọwọ́ kan ohun a àìmọ́ yálà òkú ẹranko aláìmọ́ tàbí òkú ẹran ̀sìn aláìmọ́ tàbí òkú ̀yówù ń rìn lórí ilẹ̀ ó tilẹ̀ jẹ́ ẹni náà mọ̀, ó ti di aláìmọ́, ó ti jẹ̀bi. 3 Tàbí ó fọwọ́ kan ohun àìmọ́ ti ènìyàn, ohunkóhun ènìyàn di aláìmọ́, ó tilẹ̀ jẹ́ ẹni náà mọ̀, nígbà ó mọ̀ nípa rẹ̀ yóò jẹ̀bi. 4 Tàbí ẹni kan búra láti ṣe ohun kan láì ronú e lórí, yálà ohun dára tàbí ohun búburú, nínú ̀rọ̀ yówù ti búra láì kíyèsi ara, ó tilẹ̀ jẹ́ , mọ̀ nípa rẹ̀ tẹ́lẹ̀, ó ti , nígbà mọ̀ yóò jẹ̀bi. 5 ẹnikẹ́ni jẹ̀bi ̀kan nínú àwọn nǹkan wọ̀nyí, ó gbọdọ̀ jẹ́wọ́ irú ̀ti dẹ́ṣẹ̀ 6 àti gẹ́gẹ́ ìtánràn fún ̀ṣẹ̀ ó ṣẹ̀, ó gbọdọ̀ wa fún Olúwa, abo àgùntàn tàbí abo ewúrẹ́ láti inú agbo ẹran gẹ́gẹ́ ẹbọ ̀ṣẹ̀, àlùfáà yóò ṣe ètùtù fún ̀ṣẹ̀ ó ṣẹ̀.

7 " lágbára àti ̀dọ́-àgùntàn , ó àdàbà méjì tàbí ọmọ ẹyẹlé méjì fún Olúwa gẹ́gẹ́ ìtánràn fún ̀ṣẹ̀ rẹ̀—̀kan fún ẹbọ ̀ṣẹ̀, èkejì fún ẹbọ sísun. 8 ó wọn fún àlùfáà yóò kọ́kọ́ ẹbọ ̀ṣẹ̀ ó yín in lọ́rùn, ṣùgbọ́n ó orí rẹ̀ tan, 9 ó wọ́n díẹ̀ lára ̀jẹ̀ ẹbọ ̀ṣẹ̀ náà ̀gbẹ́ pẹpẹ, ìyókù ̀jẹ̀ náà ni ó ro ìsàlẹ̀ pẹpẹ. Ẹbọ ̀ṣẹ̀ ni. 10 Lẹ́yìn èyí àlùfáà yóò ẹbọ sísun gẹ́gẹ́ ìlànà, yóò ṣe ètùtù fún un nítorí ̀ṣẹ̀ ó ṣẹ̀, a ó dáríjì í.

11 " ó jẹ́ agbára àti àdàbà méjì tàbí ọmọ ẹyẹlé méjì , ó ìdámẹ́wàá òsùwọ̀n ìyẹ̀fun kíkúnná dáradára fún ẹbọ ̀ṣẹ̀ rẹ, gbọdọ̀ fi òróró tàbí tùràrí i nítorí ẹbọ ̀ṣẹ̀ ni. 12 ó gbé e ̀dọ̀ àlùfáà, àlùfáà yóò bu ̀kúnwọ́ ìyẹ̀fun gẹ́gẹ́ ẹbọ ìrántí, ó sun ún lórí pẹpẹ, gẹ́gẹ́ ẹbọ a fi iná sun Olúwa. Ẹbọ ̀ṣẹ̀ ni. 13 Báyìí ni àlùfáà yóò ṣe ètùtù fún ẹni náà fún èyíkéyìí nínú àwọn ̀ṣẹ̀ ó , a ó dáríjì í: ìyókù jẹ́ ti àlùfáà, ẹbọ ohun jíjẹ.’ "

Ẹbọ ̀bi

14 Olúwa sọ fún Mose , 15 "Nígbà ẹnìkan dẹ́ṣẹ̀ ìrékọjá ó ṣe láìmọ̀ ti àwọn ohun mímọ́ Olúwa, ó àgbò láti inú agbo ẹran fún Olúwa gẹ́gẹ́ ìtánràn, àgbò lábùkù ó níye lórí gẹ́gẹ́ iye owó ibi mímọ́. Ẹbọ ̀bi ni. 16 ó ṣe àtúnṣe nítorí ̀ṣẹ̀ ó ti ṣẹ̀ nínú ti àwọn ohun mímọ́, ó fi ìdámárùn-ún kún iye rẹ̀, ó gbogbo rẹ̀ fún àlùfáà. Àlùfáà yóò fi àgbò ẹbọ ̀ṣẹ̀ náà ṣe ètùtù fún, a ó dáríjì í.

17 "ẹnìkan dẹ́ṣẹ̀ ó ṣe ohun yẹ ko ṣe ̀kan nínú òfin Olúwa, tilẹ̀ mọ̀, ó jẹ̀bi, yóò ru ̀bi ̀ṣẹ̀ rẹ̀ 18 ó àgbò kan láti inú agbo ẹran sọ́dọ̀ àlùfáà, fún ẹbọ ̀ṣẹ̀ àgbò lábùkù ó níye lórí iye owó ibi mímọ́. Báyìí ni àlùfáà yóò ṣe ètùtù fún ẹni náà, fún àṣìṣe ó ṣe láìmọ̀, a ó dáríjì í. 19 Ẹbọ ̀bi ni, ó ti jẹ̀bi ̀ṣẹ̀ ó ṣẹ̀ Olúwa."

Veja também

Bíblia Online Bíblia Online

Bíblia Online • Versão: 2026-07-05_19-25-13-