Pular para o conteúdo
Publicidade

Nehemiah 2

Artasasta rán Nehemiah lọ Jerusalẹmu

1 oṣù Nisani, ogún ọdún ìjọba ọba Artasasta, nígbà a gbé wáìnì fún un, mo gbé wáìnì náà, mo fi fún ọba, ìbànújẹ́ hàn ojú mi iwájú rẹ̀. 2 Nítorí náà ni ọba béèrè lọ́wọ́ mi , "Èéṣe ojú rẹ fi fàro nígbà rẹ̀ ́? Èyí í ṣe ohun mìíràn ṣe ìbànújẹ́ ọkàn."

̀gidigidi, 3 ṣùgbọ́n mo fún ọba , "ọba ó pẹ́! Èéṣe ojú mi ko ṣe fàro, nígbà ìlú a sin àwọn baba mi ahoro, a ti fi iná run àwọn ibodè rẹ̀?"

4 Ọba fún mi , "ni ìwọ ń fẹ́?"

Nígbà náà, ni mo gbàdúrà Ọlọ́run ̀run, 5 mo ọba lóhùn , "Ti ó wu ọba, ìránṣẹ́ rẹ ojúrere ojú rẹ, jẹ́ ó rán mi lọ ìlú náà Juda níbi a sin àwọn baba mi nítorí èmi tún un kọ́."

6 Nígbà náà ni ọba, pẹ̀ìyàwó rẹ̀ ó jókòó lẹ́gbẹ̀́ rẹ̀, bi , "Báwo ni ìrìnàjò náà yóò ṣe pẹ́ , nígbà wo ni ìwọ yóò padà?" Ó dùn mọ́ ọba láti rán mi lọ, bẹ́̀ ni mo àkókò kan.

7 Mo tún fún ọba , "ó wu ọba, ó fún mi lẹ́àwọn baálẹ̀ òkè odò Eufurate wọ́n le mi kọjá títí èmi yóò fi Juda láìléwu. 8 èmi gba lẹ́kan lọ́wọ́ fún Asafu, olùṣọ́ igbó ọba, nítorí ó fún mi igi láti fi ṣe àtẹ́rígbà fún ibodè ilé ìṣọ́ tẹmpili àti fún odi ìlú náà àti fún ilé èmi yóò gbé?" Nítorí ọwọ́ àánú Ọlọ́run mi lórí mi, ọba fi ìbéèrè mi fún mi. 9 Bẹ́̀ ni mo lọ ̀dọ̀ àwọn baálẹ̀ agbègbè Eufurate, mo fún wọn àwọn lẹ́ọba. Ọba ti rán àwọn ológun àti àwọn ẹlẹ́ṣin ogun pẹ̀mi.

10 Nígbà Sanballati ará Horoni àti Tobiah ará a Ammoni wọ́n jẹ́ ìjòyè gbọ́ nípa èyí , ẹnìkan láti ìtẹ̀síwájú àlàáfíà àwọn ará Israẹli inú wọn gidigidi.

Nehemiah bẹ àwọn odi Jerusalẹmu

11 Mo lọ Jerusalẹmu, lẹ́yìn ìgbà mo dúró níbẹ̀ fún ọjọ́ mẹ́ta. 12 Mo jáde òru pẹ̀àwọn ọkùnrin díẹ̀. Èmi sọ fún ẹnìkankan ohun Ọlọ́run mi ti fi ọkàn mi láti ṣe fún Jerusalẹmu. ẹranko kankan pẹ̀mi, ṣe ̀kan ṣoṣo mo gùn.

13 òru, mo jáde lọ àfonífojì ibodè ìhà kànga Jakali àti ẹnu ibodè Ààtàn àti ẹnu ibodè rẹ̀ èyí ó ti odi Jerusalẹmu ó lulẹ̀, a ti fi iná sun. 14 Nígbà náà ni mo lọ ẹnu ibodè orísun àti adágún omi ọba, ṣùgbọ́n ààyè fún ẹranko mi láti kọjá; 15 bẹ́̀ ni mo gòkè àfonífojì òru, mo ń wo odi. ìparí, mo padà sẹ́yìn, mo tún wọlé láti ibodè àfonífojì. 16 Àwọn olórí mọ ibi mo lọ tàbí mọ ohun mo ń ṣe, nítorí èmi ì sọ fún àwọn ará Júù tàbí àwọn àlùfáà tàbí àwọn ọlọ́tàbí àwọn ìjòyè tàbí ẹnikẹ́ni mìíràn yóò máa ṣe iṣẹ́ náà.

17 Nígbà náà ni mo sọ fún wọn , "Ṣé wàhálà a ni: Jerusalẹmu nínú ìparun, ibodè rẹ̀ ni a ti fi iná . , jẹ́ a tún odi Jerusalẹmu mọ, àwa jẹ́ ẹni ̀gàn mọ́". 18 Èmi tún sọ fún wọn nípa ọwọ́ àánú Ọlọ́run mi ṣe lára mi àti ohun ọba ti sọ fún mi.

Wọ́n dáhùn , "jẹ́ a bẹ̀rẹ̀ àtúnmọ rẹ̀." Bẹ́̀ ni wọ́n bẹ̀rẹ̀ iṣẹ́ rere yìí.

19 Ṣùgbọ́n nígbà Sanballati ará a Horoni, Tobiah ara olóyè Ammoni àti Geṣemu ará a Arabia gbọ́ nípa rẹ̀, wọ́n fi ṣe ẹlẹ́, wọ́n fi ṣe ̀sín. Wọ́n béèrè , "ni èyí ń ṣe yìí? Ṣé ń ṣọ̀tẹ̀ ọba ni?"

20 Mo wọn lóhùn, mo fún wọn , "Ọlọ́run ̀run yóò fún wa àṣeyọrí. Àwa ìránṣẹ́ rẹ̀ yóò bẹ̀rẹ̀ láti tún un mọ, ṣùgbọ́n fún un yin, ̀yin ìpín tàbí ipa tàbí ̀tọ́ ohunkóhun ó jẹ mọ́ ìtàn Jerusalẹmu."

Veja também