Pular para o conteúdo
Publicidade

1 Reis 19

Elijah sálọ Horebu

1 Ahabu sọ gbogbo ohun Elijah ti ṣe fún Jesebeli àti ó ti fi idà pa gbogbo àwọn wòlíì. 2 Nítorí náà Jesebeli rán oníṣẹ́ kan Elijah , "àwọn òrìṣà ó ṣe mi àti bẹ́̀ lọ pẹ̀, èmi ṣe ̀rẹ ̀kan nínú wọn ìwòyí ̀la."

3 Elijah bẹ̀, ó fún ̀rẹ̀. Nígbà ó Beerṣeba ti Juda, ó fi ọmọ ̀dọ̀ rẹ̀ sílẹ̀ níbẹ̀, 4 nígbà òun tìkára rẹ̀ lọ ìrìn ọjọ́ kan aginjù, ó ibi igi ọwọ̀ kan, ó jókòó lábẹ́ rẹ̀, ó gbàdúrà òun le , , "Mo ti , Olúwa, gba ̀mi kúrò; nítorí èmi sàn ju àwọn baba mi lọ." 5 Nígbà náà ni ó dùbúlẹ̀ lábẹ́ igi, ó sùn lọ.

ó, angẹli fi ọwọ́ tọ́ , ó , "Dìde, o jẹun." 6 Ó ó yíká, àkàrà a dín lórí ̀yín iná, àti orù-omi lẹ́bàá orí rẹ̀. Ó jẹ, ó mu, ó tún dùbúlẹ̀.

7 Angẹli Olúwa tún padà lẹ́̀kejì, ó tún fi ọwọ́ tọ́ , ó , "Dìde, ó jẹun, nítorí ìrìnàjò náà fún ." 8 Ó si dìde, ó jẹ, ó mu, o fi agbára oúnjẹ yìí lọ ogójì ̀sán àti ogójì òru Horebu, òkè Ọlọ́run. 9 Níbẹ̀, ó lọ ibi ihò òkúta, ó wọ̀ níbẹ̀.

Olúwa farahan Elijah

̀rọ̀ Olúwa tọ Elijah , "ni ìwọ ń ṣe níhìn-ín yìí, Elijah?"

10 19.10: Ro 11.2,3. Ó dáhùn , "Èmi ti ń jowú fún Olúwa Ọlọ́run àwọn ọmọ-ogun. Àwọn ọmọ Israẹli ti kọ májẹ̀rẹ sílẹ̀, wọ́n ti àwọn pẹpẹ rẹ lulẹ̀, wọ́n ti fi idà pa àwọn wòlíì rẹ. Èmi nìkan ṣoṣo ni ó , wọ́n ń ̀mi láti gbà á kúrò báyìí."

11 Olúwa , "Jáde lọ, o dúró lórí òkè níwájú Olúwa, nítorí Olúwa fẹ́ rékọjá."

Nígbà náà ni ìjì ńlá àti líle fa àwọn òkè ńlá ya, ó fọ́ àwọn àpáta túútúú níwájú Olúwa; ṣùgbọ́n Olúwa nínú ìjì náà. Lẹ́yìn ìjì náà ni ìṣẹ̀lẹ̀-ìrilẹ̀, ṣùgbọ́n Olúwa nínú ìṣẹ̀lẹ̀-ìrilẹ̀ náà. 12 Lẹ́yìn ìṣẹ̀lẹ̀-ìrilẹ̀ náà ni iná , ṣùgbọ́n Olúwa nínú iná náà. Àti lẹ́yìn iná náà ni ohùn kẹ́lẹ́ kékeré . 13 Nígbà Elijah gbọ́ , ó fi agbádá rẹ̀ bo ojú rẹ̀, ó jáde lọ, ó dúró ẹnu ihò òkúta náà.

Nígbà náà ni ohùn kan tọ̀ ́ , "ni ìwọ ń ṣe níhìn-ín, Elijah?"

14 Ó dáhùn , "Èmi ti ń jowú fún Olúwa Ọlọ́run àwọn ọmọ-ogun. Àwọn ọmọ Israẹli ti kọ májẹ̀rẹ sílẹ̀, wọ́n ti pẹpẹ rẹ lulẹ̀, wọ́n ti fi idà pa àwọn wòlíì rẹ. Èmi nìkan ṣoṣo ni ó , wọ́n ń gbìyànjú láti pa èmi náà báyìí."

15 Olúwa fún un , "Padà lọ ̀ìwọ ti , o lọ aginjù Damasku. Nígbà ìwọ ibẹ̀, fi òróró yan Hasaeli ọba lórí Aramu. 16 Tún fi òróró yan Jehu ọmọ Nimṣi ọba lórí Israẹli, àti o fi òróró yan Eliṣa ọmọ Ṣafati, ará Abeli-Mehola wòlíì ipò rẹ. 17 Jehu yóò pa ẹni ó sálà kúrò lọ́wọ́ idà Hasaeli, Eliṣa yóò pa ẹni ó sálà kúrò lọ́wọ́ idà Jehu. 18 Síbẹ̀, èmi ti pa ̀́dẹ́gbàárin (7,000) ènìyàn mọ́ fún ara mi Israẹli, àní gbogbo eékún ì ì kúnlẹ̀ fún òrìṣà Baali, àti gbogbo ẹnu ì ì fi ẹnu ó ẹnu."

Ìpè Eliṣa

19 Bẹ́̀ ni Elijah lọ kúrò níbẹ̀, ó Eliṣa ọmọ Ṣafati. Ó ń fi àjàgà màlúù méjìlá tulẹ̀ níwájú rẹ̀, àti òun náà níwájú èkejìlá. Elijah tọ̀ ́ lọ, ó da agbádá rẹ̀ ó. 20 Nígbà náà ni Eliṣa fi àwọn màlúù sílẹ̀, ó sáré tọ Elijah lẹ́yìn. Ó , "Èmi bẹ̀ ́, jẹ́ èmi lọ fi ẹnu ko baba àti ìyá mi ẹnu. Nígbà náà ni èmi yóò tọ̀ ́ lẹ́yìn."

Elijah dáhùn , "Padà sẹ́yìn, ni mo fi ṣe ́?"

21 Eliṣa fi í sílẹ̀, ó padà sẹ́yìn. Ó àjàgà màlúù rẹ, ó pa wọ́n. Ó fi ohun èlò àwọn màlúù náà bọ́ ẹran wọn, ó fi fún àwọn ènìyàn, wọ́n jẹ. Nígbà náà ni ó dìde láti tọ Elijah lẹ́yìn, ó ṣe ìránṣẹ́ fún un.

Veja também